Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 26

Isaaki àti Abimeleki

1 Ìyàn kan ilẹ̀ náà, yàtọ̀ fún èyí ó ìgbà ayé Abrahamu, Isaaki lọ sọ́dọ̀ Abimeleki ọba àwọn Filistini ni Gerari. 2 Olúwa fi ara han Isaaki, ó , "ṣe sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti, jókòó ilẹ̀ èmi ó fún . 3 26.3,4: Gẹ 22.16-18.Máa ṣe àtìpó ilẹ̀ yìí fún ìgbà díẹ̀, èmi ó pẹ̀rẹ, èmi yóò bùkún fún . Nítorí ìwọ àti irú-ọmọ rẹ ni èmi yóò fi gbogbo àwọn ilẹ̀ wọ̀nyí fún, èmi yóò fi ìdí ìbúra mo ṣe fún Abrahamu baba rẹ múlẹ̀. 4 Èmi yóò sọ ìran rẹ di púpọ̀ ìràwọ̀ ojú ̀run, èmi yóò fi gbogbo ilẹ̀ yìí fún irú àwọn ọmọ rẹ, àti nípasẹ̀ irú-ọmọ rẹ ni a ó bùkún fún gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, 5 nítorí Abrahamu gba ohùn mi gbọ́, ó pa gbogbo ìkìlọ̀, àṣẹ, ìlànà àti òfin mi mọ́." 6 Nítorí náà Isaaki jókòó Gerari.

7 26.7: Gẹ 12.13; 20.2. Nígbà àwọn ọkùnrin ìlú náà bi í léèrè ti aya rẹ̀, ó , "Arábìnrin mi í ṣe," nítorí ó bẹ̀láti jẹ́wọ́ , "Aya mi ni." Ó ń , "àwọn ọkùnrin ibẹ̀ náà ba à pa nítorí Rebeka, nítorí òun ẹwà púpọ̀."

8 Nígbà Isaaki ti níbẹ̀ fún ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́, Abimeleki ọba Filistini yọjú lójú fèrèsé, ó Isaaki ń Rebeka aya rẹ̀ tage. 9 Nígbà náà ni Abimeleki ránṣẹ́ pe Isaaki ó fun , "Nítòótọ́, aya rẹ ni obìnrin yìí í ṣe, èéṣe ìwọ fi fún wa arábìnrin mi ni?"

Isaaki fèsì , "Nítorí mo mo le pàdánù ̀mi nítorí rẹ̀."

10 Nígbà náà ni Abimeleki dáhùn , "Èwo ni èyí ìwọ ṣe wa yìí? ̀kan nínú àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti a lòpọ̀ ń kọ́? Ìwọ ìbá ̀bi sórí wa."

11 Nígbà náà ni Abimeleki pàṣẹ fún gbogbo ènìyàn , "Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan ọkùnrin yìí tàbí aya rẹ̀ yóò jẹ̀bi ikú."

12 ọdún náà, Isaaki gbin ohun ̀gbìn ilẹ̀ náà, ó kórè rẹ̀ ìlọ́po ọgọ́rùn-ún ọdún ni ọdún kan náà, nítorí Olúwa bùkún un. 13 Ọkùnrin náà di ọlọ́rọ̀ púpọ̀, ọrọ̀ rẹ̀ ń pọ̀ si, títí ó fi di ènìyàn ńlá. 14 Ó ̀pọ̀lọpọ̀ ẹran ̀sìn àti agbo ẹran àti àwọn ìránṣẹ́ bẹ́̀ àwọn Filistini ń ṣe ìlara rẹ̀. 15 Nítorí náà àwọn ará Filistini ru erùpẹ̀ di gbogbo kànga àwọn ìránṣẹ́ Abrahamu baba rẹ̀ ti gbẹ́.

16 Nígbà náà ni Abimeleki fún Isaaki , "Jáde kúrò ilẹ̀ wa, nítorí ìwọ ti di alágbára púpọ̀ lọ."

17 Isaaki ṣí kúrò níbẹ̀, ó pàgọ́ àfonífojì Gerari ó ń gbé ibẹ̀. 18 Isaaki ṣe àtúngbẹ́ àwọn kànga Abrahamu baba rẹ̀ ti gbẹ́ nígbà ayé rẹ̀, èyí àwọn Filistini ti lẹ́yìn ikú Abrahamu baba rẹ̀, ó fún wọn lórúkọ baba rẹ̀ ti sọ wọ́n tẹ́lẹ̀.

19 Àwọn ìránṣẹ́ Isaaki gbẹ́ kànga àfonífojì náà, wọ́n kan ìsun omi níbẹ̀. 20 Ṣùgbọ́n àwọn darandaran Gerari ń àwọn darandaran Isaaki kànga náà àwọn ni àwọn ni í. Nítorí náà ni ó fi pe orúkọ kànga náà Eseki, nítorí wọ́n a kànga náà. 21 Àwọn ìránṣẹ́ Isaaki tún gbẹ́ kànga mìíràn, wọ́n tún nítorí rẹ̀ pẹ̀, ó sọ orúkọ rẹ̀ Sitna. 26.21 tí ó túmọ̀ sí kànga àtakò 22 Ó tún kúrò níbẹ̀, ó gbẹ́ kànga mìíràn, wọn jásí èyí rárá, ó pe orúkọ rẹ̀ Rehoboti, ó , "Nísinsin yìí, Olúwa ti fi ààyè gbà , a ó gbilẹ̀ si ilẹ̀ náà."

23 Láti ibẹ̀, ó kúrò lọ Beerṣeba. 24 òru ọjọ́ ó ibẹ̀, Olúwa fi ara hàn án, ó , "Èmi ni Ọlọ́run Abrahamu baba rẹ. ṣe bẹ̀nítorí èmi pẹ̀rẹ, èmi yóò bùsi fún , èmi yóò sọ iye ìran rẹ di púpọ̀, nítorí Abrahamu ìránṣẹ́ mi."

25 Isaaki kọ́ pẹpẹ kan síbẹ̀, ó pe orúkọ Olúwa. Níbẹ̀ ni ó pàgọ́ rẹ̀ , àwọn ìránṣẹ́ rẹ gbẹ́ kànga kan níbẹ̀.

26 26.26: Gẹ 21.22. Nígbà náà ni Abimeleki tọ̀ ́ láti Gerari, àti Ahussati, olùdámọ̀ràn rẹ̀ àti Fikoli, olórí ogun rẹ̀. 27 Isaaki bi wọ́n léèrè , "Èéṣe ̀yin tọ̀ , níwọ̀n ìgbà ̀yin kórìíra mi mi jáde kúrò lọ́dọ̀ yín?"

28 Wọ́n dáhùn , "A i dájú Olúwa pẹ̀rẹ, nítorí náà ni a fi ó , ó yẹ májẹ̀o láàrín àwa àti ìwọ. Jẹ́ a ṣe àdéhùn 29 ìwọ yóò ṣe ibi, àwa pẹ̀ti ṣe ́ aburú, a ń ṣe ́ dáradára, a rán jáde àlàáfíà láìṣe ́ ibi, kíyèsi Olúwa ti bùkún fún ."

30 Isaaki ṣe àsè fún wọn, wọn jẹ, wọ́n mu. 31 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì wọn búra fún ara wọn. Isaaki rán wọn lọ, wọ́n lọ àlàáfíà.

32 ọjọ́ náà gan an ni àwọn ìránṣẹ́ Isaaki sọ fún un àwọn ti kan omi kànga kan àwọn gbẹ́. 33 26.33: Gẹ 21.31.Ó pe orúkọ kànga náà Ṣiba, 26.33 tí ó túmọ̀ sí, kànga májẹ̀mú títí di òní olónìí, orúkọ ìlú náà ni Beerṣeba.

34 Nígbà Esau ọmọ ogójì ọdún ó fẹ́ ọmọbìnrin kan a ń Juditi, ọmọ Beeri, ará Hiti, ó tún fẹ́ Basemati, ọmọ Eloni ará Hiti. 35 Fífẹ́ a fẹ́ àwọn obìnrin wọ̀nyí jẹ́ ìbànújẹ́ fún Isaaki àti Rebeka.

Veja também