Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 27

Jakọbu sálọ ̀dọ̀ Labani

41 Esau kórìíra Jakọbu nítorí ìre baba rẹ̀ fún un, ó fún ara rẹ̀ , "Baba mi à ti fẹ́rẹ , nígbà náà ni èmi ó pa Jakọbu, arákùnrin mi."

42 Nígbà Rebeka gbọ́ ohun Esau àkọ́rẹ̀ , ó ránṣẹ́ Jakọbu, ó fun un , "Esau ̀gbọ́n rẹ ń tu ara rẹ̀ nínú pẹ̀èrò à ti pa ́. 43 Nítorí náà ọmọ mi, ṣe ohun èmi yóò sọ fún , sálọ sọ́dọ̀ Labani ̀gbọ́n mi Harani. 44 Jókòó ibẹ̀ títí di ìgbà ìbínú ̀gbọ́n rẹ yóò fi rọ̀. 45 Nígbà ̀gbọ́n rẹ bínú mọ́, ó ti gbàgbé ohun ìwọ ṣe i, èmí ó ránṣẹ́ láti padà . Èéṣe èmi ó fi pàdánù ̀yin méjèèjì ọjọ́ kan náà?"

Veja também