Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 29

Jakọbu Padani-Aramu

1 Jakọbu tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò rẹ̀, ó ilẹ̀ àwọn ará ìlà-oòrùn. 2 Ó kànga kan pápá, agbo àgùntàn mẹ́ta dúró láti mu omi ibi kànga náà, nítorí láti inú kànga náà ni wọ́n ti ń fi omi fún agbo àgùntàn. Òkúta a gbé ẹnu kànga náà tóbi gidigidi. 3 Nígbà gbogbo agbo ẹran péjọpọ̀ ibẹ̀ tán ni àwọn darandaran yóò òkúta náà kúrò, wọn yóò fún àwọn ẹran náà omi, wọ́n ti ṣe bẹ́̀ tán, wọn yóò tún òkúta náà padà ẹnu kànga náà.

4 Jakọbu béèrè lọ́wọ́ àwọn darandaran náà , "̀yin arákùnrin mi níbo ni ̀yin ti ?"

Àwọn náà dáhùn , "Láti Harani ni."

5 Ó bi wọ́n , "Ǹjẹ́ mọ Labani ọmọ ọmọ Nahori?"

Wọ́n dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àwa mọ̀ ́n."

6 Jakọbu béèrè , "Ṣe àlàáfíà ni ó ?"

Wọ́n dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àlàáfíà ni. ó, Rakeli ọmọ rẹ̀ ni ó ń bọ̀ yìí pẹ̀agbo àgùntàn."

7 Ó , "Kíyèsi, ilẹ̀ ò ì ṣú, í àkókò fún àwọn ohun ̀sìn láti wọ̀. fún àwọn ẹran wọ̀nyí omi, ba à le tètè wọ́n padà láti jẹun."

8 Wọ́n a lóhùn , "Àwa í òkúta kúrò ẹnu kànga láti pọn omi fún àwọn ẹran títí gbogbo àwọn darandaran àti àwọn ẹran yóò fi péjọ tán."

9 wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni Rakeli pẹ̀agbo àgùntàn baba rẹ̀, nítorí darandaran ni òun náà. 10 Nígbà Jakọbu Rakeli ọmọbìnrin Labani í ṣe ̀gbọ́n ìyá rẹ̀, pẹ̀àgùntàn Labani, Jakọbu súnmọ́ kànga náà, ó òkúta kúrò lẹ́nu rẹ̀, ó fún àwọn ẹran arákùnrin ìyá rẹ̀ Labani omi. 11 Jakọbu fẹnu ko Rakeli ẹnu. Ó bẹ̀rẹ̀ í sọkún. 12 Jakọbu fún Rakeli ìbátan baba rẹ̀ ni òun, àti , òun jẹ́ ọmọ Rebeka. Rakeli sáré lọ sọ fún baba rẹ̀.

13 kété Labani gbúròó Jakọbu ọmọ arábìnrin rẹ̀, ó jáde lọ pàdé Jakọbu, ó mọ́ ọn, ó fi ẹnu ó ẹnu, ó un lọ ilé. Nígbà náà ni Jakọbu ròyìn ohun gbogbo fún un. 14 Labani , "Ẹran-ara àti ̀jẹ̀ ara mi ni ìwọ jẹ́."

Jakọbu fẹ́ àwọn ọmọ Labani Lea àti Rakeli

Lẹ́yìn Jakọbu pẹ̀rẹ̀ fún odidi oṣù kan, 15 Labani fún Jakọbu , "a tilẹ̀ jẹ́ ìbátan, yẹ o máa ṣiṣẹ́ fún mi lásán láìgba ohun kankan. Sọ ohun ìwọ fẹ́ gbà fún iṣẹ́ ìwọ ń ṣe fún mi!"

16 Wàyí o, Labani ọmọbìnrin méjì, orúkọ èyí ̀gbọ́n ń jẹ́ Lea, orúkọ àbúrò ń jẹ́ Rakeli. 17 Lea ẹwà púpọ̀, ṣùgbọ́n Rakeli ẹwà gidigidi. Ojú rẹ̀ fanimọ́ra. 18 Jakọbu fẹ́ràn Rakeli, ó fún baba rẹ̀ , "Èmi yóò ṣiṣẹ́ sìn fún ọdún méje, ìwọ yóò fún mi Rakeli ọmọ rẹ aya."

19 Labani dáhùn , "Ó kúkú sàn ń fi fún , ju ń fi fún ẹlòmíràn lọ, nítorí náà ̀dọ̀ mi." 20 Jakọbu ṣiṣẹ́ sin Labani fún ọdún méje láti fẹ́ Rakeli. Àwọn ọdún wọ̀nyí dàbí ọjọ́ díẹ̀ lára rẹ̀, nítorí ó fẹ́ràn rẹ̀.

21 Jakọbu fún Labani , "Mo ti parí àsìkò a jọ ṣe àdéhùn rẹ̀, nítorí náà fún mi aya mi, òun ṣe aya fún mi."

22 Labani pe gbogbo ènìyàn ibẹ̀ jọ, ó ṣe àsè ìyàwó fún wọ́n. 23 Ṣùgbọ́n nígbà ó di òru, Labani Lea tọ Jakọbu lọ. Jakọbu a lòpọ̀. 24 Labani fi Silipa ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin fún Lea gẹ́gẹ́ ìránṣẹ́.

25 kíyèsi, nígbà ti ilẹ̀ mọ́, Jakọbu i Lea ni! Ó fún Labani , "Èwo ni ìwọ ṣe mi yìí? Ṣe nítorí Rakeli ni mo ṣe ṣiṣẹ́ sìn , èéṣe ìwọ tàn mi?"

26 Labani dáhùn , "àṣà wa mu láti fi àbúrò fún ọkọ ṣáájú ̀gbọ́n rẹ̀. 27 sùúrù parí ̀sẹ̀ ìgbéyàwó yìí náà, nígbà náà ni èmi yóò fi àbúrò rẹ̀ fún pẹ̀, ìwọ ó ṣiṣẹ́ sìn mi fún ọdún méje mìíràn."

28 Jakọbu gbà láti sin Labani fún ọdún méje mìíràn. Labani fi Rakeli ọmọ rẹ̀ fún un aya. 29 Labani fi Biliha ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin fún Rakeli ìránṣẹ́. 30 Jakọbu Rakeli náà lòpọ̀. Ó fẹ́ràn Rakeli ju Lea lọ, ó ṣiṣẹ́ sin Labani fún ọdún méje mìíràn.

Àwọn ọmọ Jakọbu

31 Nígbà Olúwa ri , Jakọbu fẹ́ràn Lea, ó ṣí i ni inú ṣùgbọ́n Rakeli yàgàn. 32 Lea lóyún, ó ọmọkùnrin kan, ó pe orúkọ rẹ̀ Reubeni, nítorí ó , "Nítorí Olúwa ti mọ ìpọ́njú mi, dájúdájú, ọkọ mi yóò fẹ́ràn mi báyìí."

33 Ó tún lóyún, ó ọmọkùnrin kan. Ó pe orúkọ rẹ̀ Simeoni, , "Nítorí Olúwa ti gbọ́ a fẹ́ràn mi, ó fi èyí fún mi pẹ̀."

34 Ó tún lóyún, ó ọmọkùnrin kan, ó , "Nígbà yìí ni ọkọ mi yóò fi ara mọ́ mi, nítorí mo ti ọmọkùnrin mẹ́ta fún un," nítorí náà ni ó ṣe pe orúkọ rẹ̀ Lefi.

35 Ó tún lóyún, ó tún jẹ́ ọmọkùnrin ni ó , ó , "Nígbà yìí ni èmi yóò yin Olúwa." Ó pe orúkọ rẹ̀ Juda. Ó dáwọ́ ọmọ bíbí dúró.

Veja também