Publicidade

Gênesis 3

Ìṣubú ènìyàn

1 Ejò à ṣe alárékérekè ju àwọn ẹranko igbó yòókù Olúwa Ọlọ́run lọ. Ó sọ fún obìnrin náà , "Ǹjẹ́ òtítọ́ ha ni Ọlọ́run , ̀yin gbọdọ̀ jẹ èso èyíkéyìí lára àwọn igi ó nínú ọgbà?"

2 Obìnrin náà ejò lóhùn , "Àwa jẹ lára àwọn èso igi ó nínú ọgbà, 3 ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ , ̀yin gbọdọ̀ jẹ lára èso igi ó láàrín ọgbà, gbọdọ̀ fi ọwọ́ kàn án, ̀yin ṣe bẹ́̀, ̀yin yóò kùú.’ "

4 Ejò fún obìnrin náà , "̀yin yóò ikúkíkú kan." 5 "Nítorí Ọlọ́run mọ̀ , ̀yin jẹ nínú rẹ̀, ojú yín yóò , ̀yin yóò dàbí Ọlọ́run, ̀yin yóò mọ rere yàtọ̀ búburú."

6 Nígbà obìnrin náà i èso igi náà dára fún oúnjẹ àti , ó dùn ún , àti ó ń ni ọgbọ́n, ó díẹ̀ níbẹ̀, ó jẹ ́. Ó díẹ̀ fún ọkọ rẹ̀, ẹni ó pẹ̀rẹ̀, òun náà jẹ ́. 7 Nígbà náà ni ojú àwọn méjèèjì , wọ́n mọ̀ àwọn ìhòhò; wọ́n rán ewé ̀pọ̀tọ́ pọ̀, wọ́n fi bo ara wọn.

8 Nígbà náà ni ọkùnrin náà àti aya rẹ̀ gbọ́ ìró Olúwa Ọlọ́run ó ti ń rìn nínú ọgbà, nígbà ojú ọjọ́ tura, wọ́n fi ara pamọ́ kúrò níwájú Olúwa Ọlọ́run àárín àwọn igi inú ọgbà. 9 Ṣùgbọ́n Olúwa Ọlọ́run pe ọkùnrin náà , "Níbo ni ìwọ ?"

10 Ó dáhùn , "Mo gbúròó rẹ̀ nínú ọgbà, ̀, nítorí , mo ìhòhò, mo fi ara pamọ́."

11 Ọlọ́run , "Ta ni ó fún ìhòhò ni ìwọ ? Ṣé ìwọ ti jẹ nínú èso igi mo pàṣẹ fún ìwọ gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀ ni?"

12 Ọkùnrin náà , "Obìnrin ìwọ fi fún mi, ni ó fún mi nínú èso igi náà, mo jẹ ́."

13 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run , "Èwo ni èyí ìwọ ṣe yìí?"

Obìnrin náà dáhùn , "Ejò ni ó tàn jẹ, mo jẹ ́."

14 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run fún ejò náà , "Nítorí ìwọ ti ṣe èyí,

"Ègún ni fún ju gbogbo ohun ̀sìn

àti gbogbo ẹranko igbó tókù lọ!

Àyà rẹ ni ìwọ yóò fi máa wọ́,

ìwọ yóò máa jẹ erùpẹ̀ ilẹ̀

gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.

15 Èmi yóò fi ̀

àárín ìwọ àti obìnrin náà,

àti àárín irú-ọmọ rẹ àti irú-ọmọ obìnrin náà;

òun yóò fọ́ orí rẹ,

ìwọ yóò ú jẹ gìgísẹ̀."

16 Ọlọ́run fún obìnrin náà ,

"Èmi yóò fi kún ìrora rẹ àkókò ìbímọ;

ni ìrora ni ìwọ yóò máa ọmọ.

̀dọ̀ ọkọ rẹ ni ìfẹ́ rẹ yóò máa ,

òun ni yóò máa ṣe àkóso rẹ."

17 Ọlọ́run fún Adamu , "Nítorí ìwọ fetí aya rẹ, ìwọ jẹ nínú èso igi mo pàṣẹ fún , Ìwọ gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀,’

"Ègún ni fún ilẹ̀ nítorí rẹ;

nínú ̀pọ̀ làálàá ni ìwọ yóò jẹ nínú rẹ̀,

gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.

18 Ilẹ̀ yóò hu ̀gún àti èṣùṣú fún ,

ewéko igbó ni ìwọ yóò máa jẹ.

19 Nínú òógùn ojú rẹ

ni ìwọ yóò máa jẹun

títí ìwọ yóò fi padà ilẹ̀,

nítorí inú ilẹ̀ ni a ti jáde ;

erùpẹ̀ ilẹ̀ à ni ìwọ,

ìwọ yóò padà di erùpẹ̀."

20 Adamu sọ aya rẹ̀ Efa nítorí òun ni yóò di ìyá gbogbo alààyè.

21 Olúwa Ọlọ́run, ̀awọ fún Adamu àti aya rẹ̀, ó fi wọ̀ wọ́n. 22 Olúwa Ọlọ́run , "Ọkùnrin náà ti dàbí ̀kan lára wa, ó mọ rere àti búburú. A gbọdọ̀ jẹ́ ó na ọwọ́ rẹ̀ ó lára èso igi ìyè ó jẹ, ó láààyè títí láéláé." 23 Nítorí náà, Olúwa Ọlọ́run e kúrò nínú ọgbà Edeni láti lọ máa ro ilẹ̀ nínú èyí a ti un jáde . 24 Lẹ́yìn ó ti ènìyàn jáde tán, ó fi àwọn kérúbù àti idà iná ó ń kọ mọ̀nàmọ́síwájú àti sẹ́yìn láti ṣọ́ ̀ó lọ ibi igi ìyè, ìhà ìlà-oòrùn ọgbà Edeni.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-