Publicidade

Gênesis 31

Jakọbu kúrò lọ́dọ̀ Labani

1 Jakọbu gbọ́ àwọn ọmọ Labani ń , "Jakọbu ti gba gbogbo ohun ìní baba wa, ó ti ọrọ̀ jọ fún ara rẹ̀ lára àwọn ohun í ṣe ti baba wa." 2 Jakọbu ṣàkíyèsí ìwà Labani òun ti padà ti àtẹ̀yìnwá.

3 Nígbà náà ni Olúwa fún Jakọbu , "Padà lọ ilẹ̀ àwọn baba à rẹ, ̀dọ̀ àwọn ará rẹ, èmi ó pẹ̀rẹ."

4 Jakọbu ránṣẹ́ pe Rakeli àti Lea pápá níbi àwọn ohun ̀sìn rẹ̀ . 5 Ó fún wọn , "Mo i ìwà baba yín mi ti padà ti tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n Ọlọ́run baba mi pẹ̀mi. 6 à mọ̀ , mo ti fi gbogbo agbára mi ṣiṣẹ́ fún baba yín, 7 síbẹ̀síbẹ̀ baba yín ti rẹ́ mi jẹ ̀̀mẹwàá ̀tọ̀̀tọ̀ ni ó ti owó iṣẹ́ mi padà. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run jẹ́ ó le è pa mi lára. 8 ó , Àwọn ẹran onílà ni yóò dúró fún owó iṣẹ́ rẹ,nígbà náà ni gbogbo àwọn ẹran ń onílà; ó , Àwọn ẹran onítótòtó ni yóò dúró fún owó iṣẹ́ rẹ,nígbà náà ni gbogbo ẹran ń bi onítótòtó. 9 Bẹ́̀ ni Ọlọ́run gba ẹran baba yín, ó fi fún mi.

10 "àsìkò àwọn ẹran ń gùn, mo la àlá mo ri àwọn òbúkọ wọ́n ń gun àwọn ẹran jẹ́ onítótòtó, onílà àti alámì. 11 Angẹli Ọlọ́run fún mi nínú àlá náà , Jakọbu.Mo , Èmi nìyí.12 Ó , Gbé ojú rẹ sókè o ó, gbogbo àwọn òbúkọ ó ń gun àwọn ẹran jẹ́ onítótòtó, onílà àti alámì, nítorí mo ti gbogbo ohun ti Labani ń ṣe . 13 Èmi ni Ọlọ́run Beteli, níbi ìwọ ti ta òróró ̀wọ́n, ìwọ jẹ́ ̀jẹ́ láti sìn mi. Nísinsin yìí, kúrò ilẹ̀ yìí kíákíá o padà ilẹ̀ ibi a gbé ti .’ "

14 Nígbà náà ni Rakeli àti Lea dáhùn , "Ìpín wo a nínú ogún baba wa? 15 Àjèjì ha kọ́ ni ó ? í ṣe torí ó nìkan, ṣùgbọ́n ó ti gbogbo owó ó gbà lórí wa tán. 16 Dájúdájú gbogbo ọrọ̀ ti Ọlọ́run gbà lọ́wọ́ baba wa fún , tiwa àti ti àwọn ọmọ wa í ṣe. Nítorí náà ohun gbogbo Ọlọ́run pàṣẹ fun láti ṣe ni ìwọ ó ṣe."

17 Nígbà náà ni Jakọbu gbé àwọn ọmọ àti aya rẹ̀ gun ìbákasẹ. 18 Ó da gbogbo agbo ẹran rẹ̀ ṣáájú pẹ̀gbogbo ọrọ̀ ó ti kójọ ni Padani-Aramu, láti lọ ̀dọ̀ Isaaki baba rẹ̀ ni ilẹ̀ Kenaani.

19 Nígbà Labani lọ láti rẹ́run àgùntàn, Rakeli àwọn ère òrìṣà ilé baba rẹ̀. 20 Síwájú i, Jakọbu tan Labani ará Aramu, nítorí sọ fún un òun ń sálọ. 21 Ó sálọ pẹ̀ohun gbogbo ó ni, ó la odò kọjá (Eufurate), ó kọrí àwọn ilẹ̀ olókè ti Gileadi.

Labani lépa Jakọbu

22 ọjọ́ kẹta ni Labani gbọ́ Jakọbu ti sálọ. 23 Ó àwọn arákùnrin rẹ̀ pẹ̀rẹ̀, ó lépa Jakọbu, ó lépa wọn fún ọjọ́ méje, ó wọn òkè Gileadi. 24 Ọlọ́run yọ Labani ará Aramu lójú àlá òru, ó fun un , "Ṣọ́ra, ṣe sọ ohunkóhun fún Jakọbu, ìbá à ṣe rere tàbí búburú."

25 Jakọbu ti pa àgọ́ rẹ̀ si orí òkè kan, nígbà Labani a. Labani àti àwọn ó pẹ̀rẹ̀ pàgọ́ wọ́n ilẹ̀ òkè Gileadi. 26 Nígbà náà ni Labani fún Jakọbu , "Èwo ni ìwọ ṣe yìí? ìwọ tàn mi, ó àwọn ọmọbìnrin mi bi ìgbèkùn a fi idà . 27 Èéṣe ìwọ yọ́ lọ ìwọ tàn mi? ìwọ sọ fún mi ìwọ ń lọ, èmi fi ayọ̀ àti orin, pẹ̀ìlù àti ohun èlò orin sìn ́. 28 Ìwọ tilẹ̀ jẹ́ èmi fi ẹnu ko àwọn ọmọ ọmọ mi lẹ́nu, pẹ̀àwọn ọmọbìnrin mi ó dìgbà? Ìwọ ṣiwèrè ohun ìwọ ṣe yìí. 29 Mo agbára láti ṣe ni ibi, ṣùgbọ́n òru àná, Ọlọ́run baba rẹ sọ fún mi , èmi ṣọ́ra, èmi ṣe sọ ohun kan fún Jakọbu, ìbá à ṣe rere tàbí búburú. 30 Nísinsin yìí, ìwọ ti lọ nítorí ìwọ fẹ́ láti padà lọ ilé baba rẹ, ṣùgbọ́n èéṣe ìwọ fi àwọn òrìṣà mi?"

31 Jakọbu Labani lóhùn , "̀ni ó mi nítorí, mo ìwọ le fi tipátipá gba àwọn ọmọbìnrin rẹ lọ́wọ́ mi. 32 Ṣùgbọ́n o ri ẹnikẹ́ni pẹ̀ère rẹ, ẹni náà di òkú. Ó tún , níwájú gbogbo ìbátan wa báyìí, ó fúnra rẹ̀, o ohunkóhun í ṣe tìrẹ, un." Jakọbu mọ̀ , Rakeli ni ó àwọn òrìṣà náà.

33 Labani lọ sínú àgọ́ Jakọbu àti ti Lea àti ti àwọn ìránṣẹ́bìnrin méjèèjì, ohunkóhun. Lẹ́yìn ìgbà ó jáde nínú àgọ́ Lea ni ó lọ àgọ́ Rakeli. 34 Rakeli gbé àwọn òrìṣà náà sínú gàárì ìbákasẹ, ó jókòó e lórí. Labani gbogbo inú àgọ́, ohunkóhun.

35 Rakeli fún baba rẹ̀ , "ṣe bínú èmi ò le dìde dúró níwájú rẹ baba à mi, ohun ó á ni , ń ṣe nǹkan oṣù lọ́wọ́." Ó àgọ́ kiri, àwọn òrìṣà ìdílé náà.

36 Inú Jakọbu, ó pe Labani ìjà , "ni ̀ṣẹ̀ mi? ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ìwọ fi ń lépa mi ̀daràn? 37 Nísinsin yìí ìwọ ti gbogbo ẹrù mi , ni ohun í ṣe tirẹ̀ ìwọ ? wọn kalẹ̀ báyìí níwájú gbogbo ìbátan rẹ àti tèmi, wọn ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwa méjèèjì.

38 "Mo ti lọ́dọ̀ rẹ fún ogún ọdún, àwọn àgùntàn tàbí ewúrẹ́ rẹ sọnù bẹ́̀ n pa ̀kan jẹ nínú àwọn àgbò rẹ. 39 Èmi ̀kankan fún nínú èyí ẹranko búburú fàya, èmi ni ó fi ara mọ́ irú àdánù bẹ́̀. Ẹrankẹ́ran wọ́n lọ, lọ́sàn án tàbí lóru, ìwọ ń gba owó rẹ̀ lọ́wọ́ mi. 40 Báyìí ni mo ; oòrùn ń pa mi lọ́sàn án, òtútù ń pa mi lóru, mo ń ṣe àìsùn. 41 Báyìí ni ohun gbogbo fún ogún ọdún mo fi nínú ilé rẹ. Ọdún mẹ́rìnlá ni mo fi sìn ́ fún àwọn ọmọbìnrin rẹ méjèèjì, mo sìn fún ọdún mẹ́fún àwọn ẹran ̀sìn, lẹ́̀mẹ́wàá ni o owó iṣẹ́ mi padà. 42 ó ṣe Ọlọ́run àwọn baba mi, Ọlọ́run Abrahamu àti ̀Isaaki pẹ̀mi ni, ìwọ ìbá ti mi jáde lọ́wọ́ òfo. Ṣùgbọ́n, Ọlọ́run ti gbogbo ìpọ́njú mi àti iṣẹ́ àṣekára mo fi ọwọ́ mi ṣe, ó kìlọ̀ fún lóru àná."

43 Labani Jakọbu lóhùn, "Tèmi ni àwọn obìnrin wọ̀nyí, ọmọ mi ni àwọn ọmọ wọ̀nyí pẹ̀, àwọn agbo ẹran yìí, tèmi ni wọ́n pẹ̀. Gbogbo ohun o wọ̀nyí, tèmi ni. ni mo le ṣe àwọn ọmọbìnrin wọ̀nyí àti àwọn ọmọ wọn wọn ? 44 , jẹ́ a májẹ̀pẹ̀ara wa, èyí yóò jẹ́ ̀àárín wa."

45 Jakọbu òkúta kan ó gbé e dúró ̀wọ́n. 46 Ó fún àwọn ìbátan rẹ̀ , "àwọn òkúta díẹ̀ jọ." Wọ́n òkúta náà jọ òkìtì wọ́n jẹun níbẹ̀. 47 Labani pe orúkọ rẹ̀ Jegari-Sahaduta, ṣùgbọ́n Jakọbu é ni Galeedi.

48 Labani , "Òkìtì yìí jẹ́ ̀láàrín èmi àti ìwọ òní." Ìdí nìyí a fi pe orúkọ rẹ̀ ni Galeedi. 49 Ó tún é ni Mispa nítorí, ó , "Olúwa ó máa ṣọ́ èmi àti ìwọ nígbà a kúrò lọ́dọ̀ ara wa tán. 50 o fìyà jẹ àwọn ọmọbìnrin mi, tàbí o fẹ́ aya mìíràn yàtọ̀ wọn, rántí , Ọlọ́run ń bẹ láàrín wa ẹlẹ́rìí ẹnikẹ́ni tilẹ̀ ."

51 Labani tún sọ síwájú fún Jakọbu , "Òkìtì àti ̀wọ̀n mo gbé kalẹ̀ láàrín èmi àti ìwọ yìí, 52 yóò jẹ́ ̀èmi ni ̀wọ̀n àti òkìtì yìí kọjá láti àti ìwọ pẹ̀yóò kọjá òkìtì tàbí ̀wọ̀n yìí láti ṣe ibi. 53 Ǹjẹ́ Ọlọ́run Abrahamu àti Ọlọ́run Nahori, àti Ọlọ́run baba wọn ṣe ìdájọ́ láàrín wa."

Jakọbu fi ̀Isaaki baba rẹ̀ búra. 54 Jakọbu ẹbọ níbẹ̀ ni orí òkè, ó pe àwọn ẹbí rẹ̀ láti jẹun. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti jẹun, ibẹ̀ náà ni wọ́n sùn ọjọ́ náà.

55 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Labani fi ẹnu ko àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ lẹ́nu àti àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ pẹ̀, ó súre fún wọn. Labani padà lọ ilé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-