Publicidade

Gênesis 40

Agbọ́àti alásè

1 pẹ́ lẹ́yìn èyí, ni agbọ́ọba àti alásè rẹ̀ ṣẹ̀ ọba Ejibiti, olúwa wọn. 2 Farao bínú méjì nínú àwọn ìjòyè rẹ̀, olórí agbọ́àti olórí alásè, 3 Ó fi wọ́n ìhámọ́ ilé olórí ̀ṣọ́, inú ̀wọ̀n ibi Josẹfu pẹ̀. 4 Olórí ̀ṣọ́ yan Josẹfu láti máa ṣe ìránṣẹ́ wọn.

Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti ìhámọ́ fún ìgbà díẹ̀. 5 Ni ̀kọ̀̀kan àwọn ọkùnrin méjèèjì náàolórí agbọ́àti olórí alásè ọba Ejibiti, a sínú túbú, àlá òru kan náà, àlá kọ̀̀kan ìtumọ̀ tirẹ̀.

6 Nígbà Josẹfu ̀dọ̀ wọn òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó ṣe àkíyèsí , inú wọn dùn. 7 Ó bi àwọn ìjòyè Farao ó pẹ̀rẹ̀ nínú ìhámọ́, nínú ilé olúwa rẹ̀ léèrè , "Èéṣe ojú yín fi fàro bẹ́̀ òní, inú yín dùn?"

8 Wọ́n , "Àwa méjèèjì ni a àlá, ẹni yóò túmọ̀ rẹ̀."

Josẹfu fún wọn , "Ọlọ́run nìkan ni ó ni ìtumọ̀. sọ àwọn àlá yín fún mi."

9 Olórí agbọ́ṣọ́ àlá rẹ̀ fún Josẹfu, , "ojú àlá mi, mo àjàrà kan (wọn ń fi èso rẹ̀ ṣe wáìnì) níwájú mi, 10 mo ̀ka mẹ́ta lórí àjàrà náà, ó yọ ̀ka tuntun, ó tanná, láìpẹ́, ó bẹ̀rẹ̀ í èso ó ti pọ́n. 11 Ife Farao lọ́wọ́ mi, mo àwọn èso àjàrà náà, mo fún un sínú ife Farao, mo gbé ife náà fún Farao."

12 Josẹfu fún un , "Èyí ni ìtumọ̀ àlá rẹ. ̀ka mẹ́ta náà dúró fún ọjọ́ mẹ́ta. 13 Láàrín ọjọ́ mẹ́ta Farao yóò jáde nínú ̀wọ̀n padà ipò rẹ, ìwọ yóò tún máa gbé ọtí fún un, gẹ́gẹ́ ìṣe rẹ àtẹ̀yìnwá. 14 Ṣùgbọ́n nígbà ohun gbogbo dára fún , rántí mi o fi àánú hàn mi. Dárúkọ mi fún Farao, o mi jáde kúrò ìhín. 15 Nítorí á mi gbé kúrò ilẹ̀ àwọn Heberu ni, àti níhìn-ín èmi ṣe ohunkóhun ó fi yẹ èmi ìhámọ́ mo ti yìí."

16 Nígbà olórí alásè i ìtumọ̀ Josẹfu fún àlá náà dára, ó fún Josẹfu , "Èmi pẹ̀àlá, mo ru agbọ̀n oúnjẹ mẹ́ta lórí. 17 Nínú agbọ̀n ó lókè, onírúurú oúnjẹ níbẹ̀ fún Farao, ṣùgbọ́n àwọn ẹyẹ ń ṣà wọ́n jẹ láti inú apẹ̀rẹ̀ náà ó lórí mi."

18 Josẹfu dáhùn, "Èyí ni ìtumọ̀ àlá rẹ. Agbọ̀n mẹ́ta náà túmọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. 19 Láàrín ọjọ́ mẹ́ta, Farao yóò sílẹ̀, yóò bẹ́ orí rẹ, yóò gbé ara rẹ kọ́ orí igi. Àwọn ẹyẹ yóò jẹ ara rẹ."

20 Ọjọ́ kẹta jẹ́ ọjọ́ ìbí Farao, ó ṣe àsè fún gbogbo àwọn ìjòyè e rẹ̀. Ó olórí agbọ́àti olórí alásè jáde kúrò nínú ̀wọ̀n. 21 Ó olórí agbọ́padà ipò ó tẹ́lẹ̀, ó ba à le máa fi ago Farao ọwọ́, 22 ṣùgbọ́n, ó so olórí alásè kọ́ sórí igi, gẹ́gẹ́ Josẹfu ti sọ fún wọn nínú ìtumọ̀ rẹ̀ àlá wọn.

23 Ṣùgbọ́n, olórí agbọ́rántí Josẹfu mọ́, tilẹ̀ ronú nípa rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-