Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 45

Josẹfu fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀

1 45.1: Ap 7.13. Josẹfu le è pa á mọ́ra mọ́ níwájú gbogbo àwọn ó dúró í. Ó sọkún sókè bẹ́̀ àwọn ó àyíká gbọ́ ohun ẹkún rẹ̀. "Jẹ́ gbogbo ènìyàn kúrò ̀dọ̀ mi." ẹnikẹ́ni lọ́dọ̀ rẹ̀ nígbà ó fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀. 2 Ó sọkún sókè kíkankíkan bẹ́̀ àwọn Ejibiti gbọ́ ohùn ẹkún rẹ̀, àwọn ilé Farao pẹ̀gbọ́ nípa rẹ̀.

3 Josẹfu fún àwọn arákùnrin rẹ̀ , "Èmi ni Josẹfu! Ṣe baba mi láààyè?" Ṣùgbọ́n àwọn arákùnrin rẹ̀ le è a lóhùn nítorí ̀wọ́n gidigidi, ẹnu wọ́n níwájú rẹ̀.

4 Nígbà náà ni Josẹfu fún àwọn arákùnrin rẹ̀ , "súnmọ́ ̀dọ̀ mi." Nígbà wọ́n ti ṣe bẹ́̀, ó , "Èmi ni Josẹfu arákùnrin yín ilẹ̀ Ejibiti! 5 Ṣùgbọ́n báyìí, ṣe banújẹ́, ṣe bínú ara yín títà ìhín, nítorí, ̀àti gba ̀yín ni Ọlọ́run ṣe rán mi ìhín ṣáájú yín. 6 Ìyàn ó ti láti ọdún méjì sẹ́yìn yìí yóò tẹ̀síwájú fún ọdún márùn-ún i nínú èyí ẹnikẹ́ni gbìn, bẹ́̀ ni wọn ni kórè. 7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run rán mi ṣáájú yín ìhín láti da irú-ọmọ yín fún un yín lórí ilẹ̀ ayé àti láti fi ìgbàlà ńlá gba ̀yín .

8 "Nítorí náà, í ṣe ̀yin ni ó rán mi ibí yìí, ṣe Ọlọ́run. Ó fi ṣe baba, Olùdámọ̀ràn fún Farao, olúwa fún gbogbo ilé Farao àti alákòóso gbogbo ilẹ̀ Ejibiti. 9 45.9-11: Ap 7.14.Nísinsin yìí, yára padà sọ́dọ̀ baba mi fun un , èyí ni ohun Josẹfu ọmọ rẹ , Ọlọ́run ti fi ṣe olúwa fún gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, sọ̀kalẹ̀ láì jáfara. 10 Ìwọ yóò gbé agbègbè Goṣeni, ìwọ yóò jìnnà mi, àwọn ọmọ rẹ àti àwọn ọmọ ọmọ rẹ, àwọn agbo ẹran rẹ àti agbo màlúù rẹ àti gbogbo ohun ìwọ . 11 Èmi yóò pèsè fún yín níbẹ̀. Nítorí ó ṣì ku ọdún márùn-ún gbáko ti ìyàn yóò fi . ìwọ àti ilé rẹ àti ohun í ṣe tìrẹ ba à di aláìní.

12 "̀yin fúnra yín àti Benjamini arákùnrin mi pẹ̀i , lóòótọ́ lóòótọ́, èmi Josẹfu ni mo ń a yín sọ̀rọ̀. 13 sọ fún baba mi nípa gbogbo ọlá a fún mi ilẹ̀ Ejibiti àti ohun gbogbo ̀yin ti , baba mi tọ̀ ìhín yìí kíákíá."

14 Nígbà náà ni ó mọ́ Benjamini arákùnrin rẹ̀, ó sọkún, Benjamini náà mọ́ ọn, pẹ̀omijé lójú. 15 Ó tún fẹnu ko gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ lẹ́nu, ó sọkún wọn lára. Lẹ́yìn èyí, Josẹfu àti àwọn arákùnrin rẹ̀ sọ̀rọ̀ pọ̀.

16 Nígbà ìròyìn náà ààfin Farao àwọn arákùnrin Josẹfu , inú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀ dùn. 17 Farao fún Josẹfu , "fún àwọn arákùnrin rẹ , Èyí ni ṣe, di ẹrù ẹranko yín padà ilẹ̀ Kenaani, 18 baba yín àti ìdílé yín tọ̀ . Èmi yóò fún un yín ibi ó dára jùlọ ilẹ̀ Ejibiti, ̀yin yóò le è gbádùn ilẹ̀ yìí.

19 "A pàṣẹ fún láti sọ fún wọn , ṣe èyí. kẹ̀kẹ́ ẹrù láti ilẹ̀ Ejibiti fún àwọn ọmọ yín àti àwọn aya yín. baba yín tọ . 20 ṣe àníyàn nípa ohun ìní yín nítorí èyí ó dára nínú ilẹ̀ Ejibiti yóò jẹ́ tiyín.’ "

21 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe èyí. Josẹfu fún wọn ni kẹ̀kẹ́ ẹrù Farao ti pàṣẹ, ó fún wọn oúnjẹ fún ìrìnàjò wọn pẹ̀. 22 Ó fún ẹni kọ̀̀kan wọn aṣọ tuntun. Ṣùgbọ́n Benjamini ni ó fún ̀́dúnrún (300) ẹyọ owó idẹ fàdákà àti ìpààrọ̀ aṣọ márùn-ún. 23 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó ránṣẹ́ baba rẹ̀: kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá ó ru àwọn ohun mèremère ilẹ̀ Ejibiti àti abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá ó ru ọkà àti oríṣìíríṣìí oúnjẹ. 24 Nígbà náà ni ó rán àwọn arákùnrin rẹ̀ lọ, wọ́n ṣe ń pínyà, ó fún wọn , "ṣe ̀o!"

25 Báyìí ni wọ́n jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti ̀dọ̀ Jakọbu baba wọn ilẹ̀ Kenaani. 26 Wọn fún un , "Josẹfu ṣì láààyè! Kódà òun ni alákòóso ilẹ̀ Ejibiti." Ẹnu ya Jakọbu, gbà wọ́n gbọ́. 27 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n sọ ohun gbogbo Josẹfu ti sọ fún wọn fún un ó kẹ̀kẹ́ ẹrù Josẹfu fi ránṣẹ́ láti gbé e padà , iyè Jakọbu, baba wọn sọ. 28 Israẹli , "Mo gbà dájúdájú , Josẹfu ọmọ mi láààyè. Èmi ó lọ i n ."

Veja também