Publicidade

Gênesis 46

Jakọbu lọ Ejibiti

1 Báyìí ni Israẹli ìrìnàjò rẹ̀ pọ̀n pẹ̀ohun gbogbo ó , nígbà ó Beerṣeba, ó ẹbọ Ọlọ́run Isaaki baba rẹ̀.

2 Ọlọ́run Israẹli sọ̀rọ̀ ojú ìran òru , "Jakọbu! Jakọbu!"

Ó dáhùn , "Èmi nìyí."

3 Ọlọ́run , "Èmi ni Ọlọ́run, Ọlọ́run baba rẹ, ṣe bẹ̀láti sọ̀kalẹ̀ lọ ilẹ̀ Ejibiti nítorí, èmi yóò sọ ́ di orílẹ̀-èdè ńlá níbẹ̀. 4 Èmi yóò sọ̀kalẹ̀ pẹ̀rẹ lọ Ejibiti, èmi yóò tún padà . Ọwọ́ Josẹfu fúnra rẹ̀ ni ìwọ yóò ."

5 Nígbà náà ni Jakọbu kúrò Beerṣeba, àwọn ọmọ Israẹli Jakọbu baba wọn àti àwọn aya wọn àti àwọn ọmọ wọn, wọ́n wọn inú kẹ̀kẹ́ ẹrù Farao fi ránṣẹ́ fún ìrìnàjò rẹ̀. 6 Wọ́n tún àwọn ohun ̀sìn wọn àti gbogbo ohun ìní wọ́n ti láti ilẹ̀ Kenaani, Jakọbu àti gbogbo irú-ọmọ rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti. 7 Ó àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin pẹ̀àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin pẹ̀àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ obìnrin, gbogbo irú-ọmọ rẹ̀ lọ Ejibiti.

8 Èyí ni orúkọ àwọn ọmọ Israẹli (Jakọbu àti ìran rẹ̀) ó sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti:

Reubeni àkọ́Jakọbu.

9 Àwọn ọmọkùnrin Reubeni:

Hanoku, Pallu, Hesroni àti Karmi.

10 Àwọn ọmọkùnrin Simeoni:

Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari àti Saulu, ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọbìnrin ará Kenaani.

11 Àwọn ọmọkùnrin Lefi:

Gerṣoni, Kohati àti Merari.

12 Àwọn ọmọkùnrin Juda:

Eri, Onani, Ṣela, Peresi àti Sera (ṣùgbọ́n Ẹri àti Onani ti ilẹ̀ Kenaani).

Àwọn ọmọ Peresi:

Hesroni àti Hamulu.

13 Àwọn ọmọkùnrin: Isakari!

Tola, Pua, Jaṣibu àti Ṣimroni.

14 Àwọn ọmọkùnrin Sebuluni:

Seredi, Eloni àti Jahaleli.

15 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin Lea ó fún Jakọbu Padani-Aramu yàtọ̀ fún Dina ọmọbìnrin rẹ̀. Àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ àti ọmọbìnrin rẹ̀ wọ̀nyí jẹ́ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n (33) lápapọ̀.

16 Àwọn ọmọkùnrin Gadi:

Sefoni, Haggi, Ṣuni, Esboni, Eri, Arodi, àti Areli.

17 Àwọn ọmọkùnrin Aṣeri:

Imina, Iṣifa, Iṣfi àti Beriah. Arábìnrin wọn ni Sera.

Àwọn ọmọkùnrin Beriah:

Heberi àti Malkieli.

18 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Jakọbu nípasẹ̀ Silipa, ẹni Labani fi fún Lea ọmọbìnrin rẹ̀. Gbogbo wọn jẹ́ mẹ́rìndínlógún lápapọ̀.

19 Àwọn ọmọkùnrin Rakeli aya Jakọbu:

Josẹfu àti Benjamini.

20 Ejibiti, Asenati ọmọbìnrin Potifẹra, alábojútó àti àlùfáà Oni, Manase àti Efraimu fún Josẹfu.

21 Àwọn ọmọ Benjamini:

Bela, Bekeri, Aṣbeli, Gera, Naamani, Ehi, Roṣi, Mupimu, Huppimu àti Ardi.

22 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin Rakeli fún Jakọbu. Wọ́n jẹ́ mẹ́rìnlá lápapọ̀.

23 Àwọn ọmọ Dani:

Huṣimu.

24 Àwọn ọmọ Naftali:

Jasieli, Guni, Jeseri, àti Ṣillemu.

25 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Biliha ẹni Labani fi fún Rakeli ọmọ rẹ̀ fún Jakọbu. Wọ́n jẹ́ méje lápapọ̀.

26 Gbogbo àwọn ó lọ pẹ̀Jakọbu Ejibiti, àwọn ó jẹ́ ìran rẹ̀ tààrà láìka àwọn aya ọmọ rẹ̀, jẹ́ ènìyàn mẹ́rìndínláàádọ́rin. 27 Pẹ̀àwọn ọmọkùnrin méjì a fún Josẹfu Ejibiti àwọn ará ilé Jakọbu ó lọ Ejibiti jẹ́ àádọ́rin lápapọ̀.

28 Jakọbu rán Juda ṣáájú rẹ̀ lọ sọ́dọ̀ Josẹfu, wọn à le mọ ̀Goṣeni. Nígbà wọ́n agbègbè Goṣeni, 29 Josẹfu tọ́kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ ó lọ Goṣeni láti pàdé Israẹli baba rẹ̀. Josẹfu ti iwájú baba rẹ̀, ó mọ́ baba rẹ̀ ó sọkún fún ìgbà pípẹ́.

30 Israẹli fún Josẹfu , "Wàyí o, mo le , níwọ̀n mo ti i fún ara mi , o láààyè síbẹ̀."

31 Nígbà náà ni Josẹfu fún àwọn arákùnrin rẹ̀ àti fún àwọn ará ilé baba rẹ̀ , "Èmi yóò gòkè lọ, èmi yóò Farao sọ̀rọ̀, èmi yóò fún un , Àwọn arákùnrin mi àti ìdílé baba mi ń gbé Kenaani ti tọ̀ . 32 Darandaran ni àwọn ènìyàn náà, wọ́n ń tọ́ẹran ̀sìn, wọ́n agbo ẹran wọn àti agbo màlúù wọn àti gbogbo ohun wọ́n pẹ̀.33 Nígbà Farao yín wọlé ó béèrè irú iṣẹ́ ń ṣe, 34 fún un lésì , Àwọn ìránṣẹ́ rẹ ń tọ́ẹran ̀sìn ni láti ìgbà èwe wa gẹ́gẹ́ a ṣe ba a lọ́wọ́ àwọn baba wa.Nígbà náà ni wọn yóò fún un yín láààyè láti tẹ̀ilẹ̀ Goṣeni, nítorí àwọn ará Ejibiti kórìíra ẹnikẹ́ni ó jẹ́ darandaran."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-