Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 50

1 Josẹfu ṣubú baba rẹ̀, ó sọkún, ó fẹnukò ó ẹnu. 2 Nígbà náà ni Josẹfu pàṣẹ fún àwọn oníṣègùn ó ìkáwọ́ rẹ̀ wọn ó ṣe òkú Israẹli baba rẹ̀ lọ́jọ̀, àwọn oníṣègùn náà ṣe bẹ́̀. 3 Fún ogójì ọjọ́ ni wọ́n fi ṣe èyí, nítorí èyí ni àsìkò a máa ń fi ṣe ̀ǹbáàmù òkú. Àwọn ará Ejibiti ṣọ̀fọ̀ rẹ̀ fún àádọ́rin ọjọ́.

4 Nígbà ọjọ́ ìṣọ̀fọ̀ náà kọjá. Josẹfu fún àwọn ará ilé Farao , "mo ojúrere yín pàdé, mi sọ fún Farao. 5 50.5: Gẹ 47.29-31.Baba mi mi búra ó fún mi , "Mo ti fẹ́rẹ : sinmi sínú ibojì mo gbẹ́ fún ara mi ilẹ̀ Kenaani." Nísinsin yìí, jẹ́ n lọ n sìnkú baba mi, lẹ́yìn náà èmi yóò padà wa.’ "

6 Farao , "Gòkè lọ, o sin baba rẹ, ó búra."

7 Báyìí ni Josẹfu gòkè lọ láti sìnkú baba rẹ̀. Gbogbo àwọn ìjòyè Farao ni ó sìn ín lọàwọn àgbàgbà ilé rẹ̀, àti gbogbo àwọn àgbàgbà ilẹ̀ Ejibiti. 8 Yàtọ̀ fún gbogbo àwọn ará ilé Josẹfu àti ti àwọn arákùnrin rẹ̀ àti àwọn ó jẹ́ ilé baba rẹ̀, àwọn ọmọ wọn nìkan àti agbo ẹran pẹ̀agbo màlúù ni ó sẹ́ Goṣeni. 9 Kẹ̀kẹ́-ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin pẹ̀gòkè lọ. Àìmoye ènìyàn ni ó lọ.

10 Nígbà wọ́n ilẹ̀ ìpakà Atadi, ̀Jordani, wọn pohùnréré ẹkún, níbẹ̀ ni Josẹfu tún dúró ṣọ̀fọ̀ baba rẹ̀ fún ọjọ́ méje. 11 Nígbà àwọn ará Kenaani ń gbé níbẹ̀ i wọ́n ti ń ṣọ̀fọ̀ náà ni ilẹ̀ ìpakà Atadi, wọ́n , "̀fọ̀ ńlá ni àwọn ará Ejibiti ń ṣe yìí." Ìdí èyí ni a fi ń pe ibẹ̀ Abeli-Misraimu.50.11 Abeli-Misraimu tí ó túmọ̀ sí, ìṣọ̀fọ̀ àwọn ará Ejibiti jìnnà Jordani.

12 Báyìí ni àwọn ọmọ Jakọbu ṣe ohun baba wọn pàṣẹ fún wọn. 13 50.13: Ap 7.16.Wọ́n gbé e lọ ilẹ̀ Kenaani, wọ́n sin ín sínú ihò àpáta ó oko Makpela, tòsí i Mamre Abrahamu gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìsìnkú lọ́wọ́ Efroni ará Hiti, pẹ̀ilẹ̀ náà. 14 Lẹ́yìn ìgbà ó ti sìnkú baba rẹ̀ tan, Josẹfu padà Ejibiti pẹ̀àwọn arákùnrin rẹ̀ àti àwọn mìíràn ó tẹ̀e lọ láti sin baba rẹ̀.

Josẹfu fi ọkàn àwọn arákùnrin rẹ̀ balẹ̀

15 Nígbà àwọn arákùnrin Josẹfu i baba wọn , wọ́n fún ara wọn , "Ǹjẹ́ ó ṣe Josẹfu ṣì fi sínú ń kọ́, ó fẹ́ gbẹ̀san gbogbo aburú a ti ṣe i?" 16 Nítorí náà wọ́n ránṣẹ́ Josẹfu , "Baba rẹ fi àṣẹ yìí sílẹ̀ ó lọ , 17 Èyí ni ̀yin ó sọ fún Josẹfu, mo bẹ̀ ́ o dáríjì àwọn arákùnrin rẹ, gbogbo ̀ṣẹ̀ àti aburú wọ́n ṣe , èyí ó ibi . Nísinsin yìí, jọ̀wọ́ dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run baba rẹ wọ́n." Nígbà iṣẹ́ ti wọ́n rán ̀dọ̀ rẹ̀, Josẹfu sọkún.

18 Àwọn arákùnrin rẹ̀ , wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n , "Ẹrú rẹ ni a jẹ́." 19 Ṣùgbọ́n Josẹfu fún wọn , "ṣe bẹ̀, èmi ha ipò Ọlọ́run ? 20 ó tilẹ̀ jẹ́ gbèrò láti ṣe mi ibi, ṣùgbọ́n Ọlọ́run gbèrò láti fi ṣe rere ń ṣe lọ́wọ́ yìí; ni gbígba ̀̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn . 21 Nítorí náà, ṣe bẹ̀. Èmi yóò pèsè fún ̀yin àti àwọn ọmọ yín." Ó tún fi wọ́n lọ́kàn balẹ̀, ó sọ ̀rọ̀ rere fun wọn.

Ikú Josẹfu

22 Josẹfu ń gbé Ejibiti pẹ̀gbogbo ìdílé baba rẹ̀. Ó láààyè fún àádọ́ọdún. 23 Ó ìran kẹta ọmọ Efraimu-Àwọn ọmọ Makiri, ọmọkùnrin Manase ni a gbé le eékún Josẹfu nígbà ó wọn.

24 Nígbà náà ni Josẹfu fún àwọn arákùnrin rẹ̀ , "Mo ti fẹ́rẹ , ṣùgbọ́n dájúdájú Ọlọ́run yóò ìrànlọ́wọ́ yín, yóò un yín jáde kúrò ilẹ̀ yìí lọ ilẹ̀ ó ti ṣèlérí ìbúra fún Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu." 25 Josẹfu àwọn ọmọ Israẹli búra májẹ̀kan , "Dájúdájú Ọlọ́run yóò ìrànlọ́wọ́ yín, nígbà náà ni gbọdọ̀ egungun mi lọ́wọ́ kúrò ìhín."

26 Báyìí ni Josẹfu nígbà ó àádọ́ọdún. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ṣe òkú rẹ̀ lọ́jọ̀ tan, a gbé e inú pósí Ejibiti.

Veja também