Publicidade

Gênesis 8

Ìkún omi gbẹ

1 Ọlọ́run rántí Noa àti ohun alààyè gbogbo ó pẹ̀rẹ̀, àwọn ẹranko igbó àti ohun ̀sìn, ó afẹ́fẹ́ fẹ́ sórí ilẹ̀, omi náà . 2 Gbogbo ìsun ibú àti fèrèsé ìṣàn ̀run , òjò pẹ̀dáwọ́ rírọ̀ dúró. 3 Omi bẹ̀rẹ̀ gbẹ kúrò lórí ilẹ̀, lẹ́yìn àádọ́jọ ọjọ́, ó ti ń . 4 ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kejì ni ọkọ̀ náà gúnlẹ̀ sórí òkè Ararati. 5 Omi náà ń gbẹ si títí di oṣù kẹwàá. ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹwàá, orí àwọn òkè farahàn.

6 Lẹ́yìn ogójì ọjọ́, Noa fèrèsé ó ṣe sára ọkọ̀. 7 Ó rán ẹyẹ ìwò kan jáde, ó ń káàkiri síwá àti sẹ́yìn títí omi fi gbẹ kúrò orí ilẹ̀. 8 Ó rán àdàbà kan jáde láti ó bóyá omi ti gbẹ kúrò lórí ilẹ̀. 9 Ṣùgbọ́n àdàbà náà ìyàngbẹ ilẹ̀ nítorí omi ì tan lórí ilẹ̀, ó padà sọ́dọ̀ Noa. Noa na ọwọ́ rẹ̀ jáde ó ẹyẹ náà wọlé sọ́dọ̀ ara rẹ̀ nínú ọkọ̀. 10 Ó dúró fún ọjọ́ méje i; ó tún rán àdàbà náà jáde láti inú ọkọ̀. 11 Nígbà àdàbà náà padà sọ́dọ̀ rẹ̀ àṣálẹ́, ó ewé igi olifi tútù ẹnu! Nígbà náà ni Noa mọ̀ omi ti ń gbẹ kúrò lórí ilẹ̀. 12 Noa tún sùúrù fún ọjọ́ méje, ó tún rán àdàbà náà jáde, ṣùgbọ́n àdàbà náà padà sọ́dọ̀ rẹ̀ mọ́.

13 ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní, ọdún kọ́kànlélẹ́gbẹ̀ta (601) ni omi náà gbẹ kúrò lórí ilẹ̀; Noa ṣí ọkọ̀, ó ri ilẹ̀ ti gbẹ. 14 ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kejì, ilẹ̀ ti gbẹ pátápátá.

15 Nígbà náà ni Ọlọ́run fún Noa . 16 "Jáde kúrò nínú ọkọ̀, ìwọ àti aya rẹ, pẹ̀àwọn ọmọ rẹ àti àwọn aya wọn. 17 gbogbo àwọn ̀alààyè ó pẹ̀rẹ jáde: àwọn ẹyẹ, ẹranko àti gbogbo àwọn ̀ń rìn nílẹ̀, wọn i, wọn pọ̀ i, wọn máa gbá yìn lórí ilẹ̀."

18 Noa, àwọn ọmọ rẹ̀, aya rẹ̀ àti àwọn aya ọmọ rẹ̀ jáde. 19 Gbogbo àwọn ẹranko àti àwọn ̀ń rìn nílẹ̀ àti gbogbo ẹyẹ pátápátá ni ó jáde kúrò nínú ọkọ̀, ̀wọ̀̀wọ́ irú tiwọn.

20 Noa mọ pẹpẹ fún Olúwa, ó lára àwọn ẹran ó mọ́ àti ẹyẹ ó mọ́, ó fi ẹbọ sísun lórí pẹpẹ. 21 Olúwa gbọ́ òórùn dídùn; ó ọkàn rẹ̀ , "Èmi yóò tún fi ilẹ̀ nítorí ènìyàn mọ, ó tilẹ̀ jẹ́ gbogbo èrò inú rẹ̀ jẹ́ ibi láti ìgbà èwe rẹ̀ , èmi yóò pa gbogbo ohun alààyè run mọ́ láé, mo ti ṣe.

22 "Níwọ́n ìgbà ayé ,

ìgbà ̀gbìn àti ìgbà ìkórè

ìgbà òtútù àti ìgbà ooru,

ìgbà ̀̀rùn àti ìgbà òjò,

ìgbà ̀sán àti ìgbà òru,

yóò títí láé."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-