Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 24

Ìbéèrè Jobu

1 "Ṣe ìgbà pamọ́ lọ́dọ̀ Olódùmarè fún ìdájọ́?

Èéṣe ojúlùmọ̀ rẹ̀ fi ọjọ́ rẹ̀?

2 Wọ́n a sún àmì ààlà ilẹ̀,

wọ́n á fi agbára agbo ẹran lọ, wọ́n a bọ́ wọn.

3 Wọ́n á da kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ aláìní baba lọ,

wọ́n a gba ̀màlúù opó ohun ògo.

4 Wọ́n á bi aláìní kúrò lójú ̀,

àwọn tálákà ayé a fi agbára pamọ́.

5 Kíyèsi i, i kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó nínú ijù ni àwọn tálákà jáde lọ iṣẹ́ wọn,

wọ́n a tètè dìde láti ohun ọdẹ;

ijù pèsè oúnjẹ fún wọn àti fún àwọn ọmọ wọn.

6 Olúkúlùkù a ọkà oúnjẹ ẹran rẹ̀ nínú oko,

wọn a ọgbà àjàrà ènìyàn búburú.

7 ìhòhò ni wọn máa sùn láìní aṣọ,

wọn ìbora nínú òtútù.

8 ̀wààrà òjò òkè ńlá pa wọ́n,

wọ́n lẹ̀ mọ́ àpáta nítorí ààbò.

9 Wọ́n ọmọ aláìní baba kúrò ẹnu ọmú,

wọ́n gbà ọmọ tálákà nítorí gbèsè.

10 Wọ́n rìn kiri ìhòhò láìní aṣọ;

àwọn ebi ń pa rẹrù ìdì ọkà.

11 Àwọn ẹni ń fún òróró nínú àgbàlá wọn,

wọ́n ń tẹ ìfúntí àjàrà, síbẹ̀ òǹgbẹ ń gbẹ wọn.

12 Àwọn ènìyàn ń kérora láti ìlú ,

ọkàn àwọn ẹni ó gbọgbẹ́ kígbe sókè fún ìrànlọ́wọ́

síbẹ̀ Ọlọ́run kíyèsi àṣìṣe náà.

13 "Àwọn ni ó nínú àwọn ó ṣọ̀tẹ̀ ìmọ́lẹ̀,

wọn mọ̀ ipa ̀rẹ̀,

bẹ́̀ ni wọn dúró nípa ̀rẹ̀.

14 Apànìyàn a dìde àfẹ̀mọ́júmọ́,

a pa tálákà àti aláìní,

àti òru a di olè.

15 Ojú alágbèrè pẹ̀dúró ilẹ̀ ṣú díẹ̀;

Ó , ojú ẹnìkan yóò mi,

ó fi ìbòjú bojú rẹ̀.

16 òkùnkùn wọn á rúnlẹ̀ wọlé,

wọ́n ti fi ojú sọ fún ara wọn ̀sán,

wọn mọ̀ ìmọ́lẹ̀.

17 Nítorí òru dúdú òwúrọ̀ fún gbogbo wọn;

nítorí wọn mọ̀ ìbẹ̀òkùnkùn.

18 "Ó yára lọ ẹni lójú omi;

ìpín wọn ilé ayé ni a ó parun;

òun rìn lọ mọ́ ̀ọgbà àjàrà.

19 Gẹ́gẹ́ bi ̀àti òru í omi òjò-dídì yọ́,

bẹ́̀ isà òkú í run àwọn dẹ́ṣẹ̀.

20 Inú ìbímọ yóò gbàgbé rẹ̀,

kòkòrò yóò máa fi adùn jẹun lára rẹ̀;

a yóò rántí ènìyàn búburú mọ́;

bẹ́̀ a ó ṣẹ ìwà búburú ẹní ṣẹ́ igi.

21 Ẹni o ìwà búburú àgàn

ṣe rere opó.

22 Ọlọ́run fi ipá agbára rẹ̀ fa alágbára,

wọ́n tilẹ̀ fìdímúlẹ̀, ìrètí ìyè fún wọn.

23 Ọlọ́run fi àìléwu fún un,

àti nínú èyí ni a ó i lẹ́yìn,

ojú rẹ̀ ipa ̀wọn.

24 A gbé wọn lékè nígbà díẹ̀, wọ́n kọjá lọ;

a rẹ̀ wọ́n sílẹ̀, a wọn kúrò ̀àwọn ẹlòmíràn,

a wọn kúrò orí síírí ọkà bàbà.

25 "Ǹjẹ́, bẹ́̀ nísinsin yìí, ta ni yóò mi èké,

yóò sọ ̀rọ̀ mi di aláìníláárí?"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também