Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 34

Elihu pe Jobu níjà

1 Nígbà náà ni Elihu dáhùn, ó ,

2 "̀yin ọlọ́gbọ́n gbọ́ ̀rọ̀ mi,

fi etí sílẹ̀ mi ̀yin ìmòye.

3 Nítorí etí a máa dán ̀rọ̀ ,

adùn ẹnu ti ń tọ́ oúnjẹ .

4 jẹ́ a mọ òye ohun o tọ́ fún ara wa;

jẹ́ a mọ ohun ó dára láàrín wa.

5 "Nítorí Jobu , Aláìlẹ́ṣẹ̀ ni èmi;

Ọlọ́run ti gba ìdájọ́ mi lọ.

6 Èmi ha purọ́ ̀tọ́ mi ,

mo tilẹ̀ jẹ́ aláìjẹ̀bi,

ọfà rẹ̀ àwòtán ọgbẹ́.’

7 Ọkùnrin wo ni ó dàbí Jobu,

ń mu ̀gàn ẹní omi?

8 ń àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀ kẹ́gbẹ́ ó

ń àwọn ènìyàn búburú rìn.

9 Nítorí ó ti , Èrè kan fún ènìyàn,

yóò fi máa ṣe inú dídùn Ọlọ́run.

10 "Ǹjẹ́ nítorí náà, fetísílẹ̀ mi,

fi etí mi ̀yin ènìyàn amòye:

Ó di èèwọ̀ fún Ọlọ́run ti ìbá fi hùwà búburú,

àti fún Olódùmarè, yóò fi ṣe àìṣedéédéé!

11 Nítorí ó ń sán fún ènìyàn fún gẹ́gẹ́ bi ohun a ṣe,

yóò olúkúlùkù ó gẹ́gẹ́ ipa ̀rẹ̀.

12 Nítòótọ́ Ọlọ́run yóò hùwàkiwà;

bẹ́̀ ni Olódùmarè yóò ìdájọ́ po.

13 Ta ni ó fi ìtọ́ayé e lọ́wọ́,

tàbí ta ni ó fi gbogbo ayé e lọ́wọ́?

14 ó gbé ayé rẹ̀ kìkì ara rẹ̀

ó gba ọkàn rẹ̀ àti ̀rẹ̀ sọ́dọ̀ ara rẹ̀,

15 gbogbo ènìyàn ni yóò parun pọ̀,

ènìyàn a tún padà di erùpẹ̀.

16 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ìwọ òye,

gbọ́ èyí; fetísí ohùn ẹnu mi.

17 Ẹni ó kórìíra òtítọ́ ha le ṣe olórí ?

Ìwọ ó ha olóòótọ́ àti ẹni ńlá lẹ́bi?

18 O ha tọ́ láti fún ọba , Ènìyàn búburú ìwọ,

tàbí fún àwọn ọmọ-aládé , Ìkà ni ̀yin,

19 mélòó mélòó fún ẹni í ṣe ojúsàájú àwọn ọmọ-aládé

tàbí ọlọ́rọ̀ ju tálákà lọ,

nítorí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni gbogbo wọn í ṣe?

20 ìṣẹ́kan ni wọn ó ,

àwọn ènìyàn á di yíyọ́ lẹ́nu láàrín ̀gànjọ́, wọn a kọjá lọ;

a àwọn alágbára kúrò láìsí ọwọ́ ènìyàn níbẹ̀.

21 "Nítorí ojú rẹ̀ ń bẹ ipa ̀ènìyàn,

òun ìrìn rẹ̀ gbogbo.

22 ibi òkùnkùn, tàbí òjìji ikú,

níbi àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀ yóò gbé pamọ́ .

23 Nítorí òun pẹ́ àti kíyèsi ẹnìkan,

òun ó lọ sínú ìdájọ́ níwájú Ọlọ́run.

24 Òun ó fọ́ àwọn alágbára túútúú láìní ìwádìí,

a fi ẹlòmíràn dípò wọn,

25 nítorí ó mọ iṣẹ́ wọn,

ó wọn po òru, bẹ́̀ ni wọ́n di ìtẹ̀mọ́lẹ̀.

26 Ó kọlù wọ́n nítorí ìwà búburú wọn

níbi àwọn ẹlòmíràn ti i,

27 nítorí wọ́n padà pẹ̀yìndà i,

wọn fiyèsí ipa ̀rẹ̀ gbogbo,

28 wọn ó igbe ẹkún àwọn tálákà lọ ̀dọ̀ rẹ̀,

òun gbọ́ igbe ẹkún aláìní.

29 Ṣùgbọ́n nígbà ó dákẹ́ síbẹ̀, ta ni yóò lẹ́bi?

Nígbà ó pa ojú rẹ̀ mọ́, ta ni yóò i?

Bẹ́̀ ni ó ṣe si orílẹ̀-èdè tàbí ènìyàn kan ṣoṣo;

30 aláìwà bi Ọlọ́run ó à jẹ ọba

wọn ó di ìdẹwò fún ènìyàn.

31 "Nítorí ẹnìkan ha fún Ọlọ́run ,

èmi jẹ̀bi, èmi ṣẹ̀ mọ́?

32 Èyí èmi ìwọ fi kọ́ mi

bi mo dẹ́ṣẹ̀ èmi yóò ṣe bẹ́̀ mọ́.

33 Ǹjẹ́ ti inú rẹ̀ ni ki òun ó san ̀ṣẹ̀ padà?

Ǹjẹ́ òun yóò san án padà ìwọ kọ̀ ́ láti jẹ́wọ́,

ìwọ gbọdọ̀ yan, í ṣe èmi.

Nítorí náà sọ ohun o mọ̀,

pẹ̀lúpẹ̀ohun ìwọ mọ̀, sọ ́!

34 "Àwọn ènìyàn amòye yóò fún mi,

àti pẹ̀lúpẹ̀ẹnikẹ́ni í ṣe ọlọ́gbọ́n ó gbọ́ mi ,

35 Jobu ti fi àìmọ̀ sọ̀rọ̀,

̀rọ̀ rẹ̀ ṣe aláìgbọ́n.

36 Ìfẹ́ mi ni a dán Jobu òpin,

nítorí ìdáhùn rẹ̀ dàbí i ti ènìyàn búburú.

37 Nítorí pe ó fi ìṣọ̀tẹ̀ kún ̀ṣẹ̀ rẹ̀;

ó pàtẹ́wọ́ àárín wa,

ó sọ ̀rọ̀ odi púpọ̀ Ọlọ́run."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também