Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 40

Jobu rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀

1 Olúwa Jobu lóhùn pẹ̀, ó ,

2 "Ẹni ń Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ̀kọ́?

Ẹni ń Ọlọ́run jẹ́ ó dáhùn!"

3 Nígbà náà ni Jobu Olúwa lóhùn ó ,

4 "Kíyèsi i, ̀gbin ni èmiohun ni èmi ó ?

Èmi ó fi ọwọ́ mi le ẹnu mi.

5 ̀̀kan mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi yóò tún sọ mọ́;

lẹ́̀kejì ni, èmi le ṣe é mọ́."

6 Nígbà náà Olúwa Jobu lóhùn láti inú ìjì àyíká , ó ,

7 "Di àmùrè gírí ẹgbẹ́ rẹ ọkùnrin,

èmi ó bi léèrè,

ìwọ ó mi lóhùn.

8 "Ìwọ ha fẹ́ ìdájọ́ mi di asán?

Ìwọ ó mi lẹ́bi, ìwọ ṣe olódodo.

9 Ìwọ ni apá Ọlọ́run

tàbí ìwọ fi ohùn sán àrá òun?

10 Fi ọláńlá àti ọlá ìtayọ rẹ̀ ṣe ara rẹ ̀ṣọ́,

ó fi ògo àti títóbi ̀ṣọ́ bo ara aṣọ.

11 ìrunú ìbínú rẹ jáde;

kíyèsí gbogbo ìwà ìgbéraga rẹ o rẹ̀ ́ sílẹ̀.

12 Wo gbogbo ìwà ìgbéraga, ènìyàn o rẹ sílẹ̀

o tẹ ènìyàn búburú mọ́lẹ̀ ipò wọn.

13 Sin gbogbo wọn papọ̀ nínú erùpẹ̀,

o di ojú ìkọ̀kọ̀ wọn isà òkú.

14 Nígbà náà èmi ó yìn ́ ,

ọwọ́ ̀tún ara rẹ gbà ́ .

15 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi Behemoti,

mo pẹ̀rẹ,

òun a máa jẹ koríko ̀màlúù.

16 o nísinsin yìí, agbára rẹ ̀gbẹ́ rẹ,

àti ipa rẹ nínú ìṣàn ìkún rẹ.

17 Òun a máa ìrù rẹ̀ i igi kedari,

iṣan itan rẹ̀ dìjọ pọ̀.

18 Egungun rẹ̀ ògùṣọ̀ idẹ,

Egungun rẹ̀ dàbí ̀irin.

19 Òun ni olórí nínú àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run;

síbẹ̀ Ẹlẹ́dàá rẹ̀ fi idà rẹ̀ e lọ́wọ́.

20 Nítòótọ́ òkè ńlá ńlá i mu ohun jíjẹ fún un ,

níbi gbogbo ẹranko igbó máa ṣiré ̀gbẹ́ ibẹ̀.

21 Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lótusì,

lábẹ́ eèsún àti ẹrẹ̀.

22 Igi lótusì síji wọn o;

igi arọrọ odò i káàkiri.

23 Kíyèsi i, odò ńlá sàn jọjọ, òun sálọ;

ó láìléwu ó ṣe odò Jordani ti ṣàn lọ ẹnu rẹ̀.

24 Ẹnìkan ha un ojú rẹ̀,

tàbí dẹkùn fún tàbí a máa fi ̀kọ̀ gún imú rẹ̀?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também