Publicidade

Jó 10

Àròyé Jobu Tẹ̀síwájú

1 "Agara ìwà ayé mi mi tán;

èmi yóò àròyé mi sókè lọ́dọ̀ mi

èmi yóò máa sọ̀rọ̀ nínú kíkorò ìbìnújẹ́ ọkàn mi.

2 Èmi yóò fún Ọlọ́run , ṣe mi lẹ́bi;

fihàn nítorí ìdí ohun ìwọ fi ń mi .

3 Ó ha tọ́ ìwọ ìbá fi máa ni lára,

ìwọ ìbá fi máa gan iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,

ìwọ yóò fi máa tàn ìmọ́lẹ̀ ìmọ̀ ènìyàn búburú?

4 Ojú rẹ ha ṣe ojú ènìyàn ?

Tàbí ìwọ a máa ríran ènìyàn ti í ríran?

5 Ọjọ́ rẹ ha dàbí ọjọ́ ènìyàn,

ọdún rẹ ha dàbí ọjọ́ ènìyàn,

6 ìwọ fi ń béèrè àìṣedéédéé mi,

ìwọ fi ̀ṣẹ̀ mi ?

7 Ìwọ mọ̀ èmi í ṣe oníwà búburú,

ẹni ó le gbà kúrò ọwọ́ rẹ?

8 "Ọwọ́ rẹ ni ó mọ mi, ó da mi.

Síbẹ̀ ìwọ tún yípadà láti jẹ run.

9 Èmi bẹ̀ ́ rántí ìwọ ti mọ amọ̀.

Ìwọ yóò ha tún mi padà lọ sínú erùpẹ̀?

10 Ìwọ ha ti jáde i wàrà,

ìwọ dìpọ̀ i wàràǹkàṣì?

11 Ìwọ ti fi àwọ̀ ẹran-ara wọ̀ ,

ìwọ fi egungun àti iṣan ṣọgbà mi .

12 Ìwọ ti fún mi ̀àti ojúrere,

ìbẹ̀rẹ pa ọkàn mi mọ́.

13 "Nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ti fi pamọ́ nínú rẹ;

èmi mọ̀ , èyí ń bẹ ọkàn rẹ.

14 mo ṣẹ̀, nígbà náà ni ìwọ yóò máa ṣọ́ mi

ìwọ yóò dárí àìṣedéédéé mi .

15 mo ṣe ẹni búburú, ègbé ni fún mi!

mo ṣe ẹni rere, bẹ́̀ ni èmi le gbe orí mi sókè,

èmi dààmú

mo si wo ìpọ́njú mi.

16 mo gbé orí mi ga, ìwọ ń dẹ kiri bi i kìnnìún

àti pẹ̀, ìwọ a fi ara rẹ hàn fún mi ìyànjú.

17 Ìwọ tún mu àwọn ẹlẹ́rìí rẹ dìde mi di ̀tún

ìwọ sọ ìrunú rẹ di púpọ̀ mi;

àwọn ogun rẹ si dìde sinmi bi igbe omi Òkun.

18 "Nítorí ni ìwọ ṣe mi jáde láti inú ?

Háà! Èmi ìbá kúkú ti , ojúkójú mi.

19 le jẹ́ èmi láààyè,

à ti gbé mi láti inú lọ isà òkú.

20 Ọjọ́ mi ha kúrú ? Rárá!

Dáwọ́ dúró, ó padà kúrò lọ́dọ̀ mi.

Nítorí èmi ni ayọ̀ ìṣẹ́kan.

21 èmi ó lọ ibi èmi yóò padà sẹ́yìn mọ́,

àní si ilẹ̀ òkùnkùn àti òjìji ikú,

22 ilẹ̀ òkùnkùn òkùnkùn tìkára rẹ̀,

àti ti òjìji ikú àti rúdurùdu,

níbi ìmọ́lẹ̀ dàbí òkùnkùn."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-