Publicidade

Jó 32

̀rọ̀ Elihu

1 Bẹ́̀ ni àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ̀̀ta wọ̀nyí dákẹ́ láti Jobu lóhùn, nítorí ó ṣe olódodo lójú ara rẹ̀. 2 Nígbà náà ni inú Elihu ọmọ Barakeli ará Busi, láti ìbátan ìdílé Ramu; ó bínú si Jobu nítorí ti ó ara rẹ̀ láre kàkà ki ó Ọlọ́run láre. 3 Inú i àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ mẹ́tẹ̀̀ta, nítorí wọn ̀láti Jobu lóhùn bẹ́̀ ni wọ́n Jobu lẹ́bi. 4 Ǹjẹ́ Elihu ti dúró títí Jobu fi sọ̀rọ̀ tán nítorí àwọn wọ̀nyí dàgbà ju òun lọ ọjọ́ orí. 5 Nígbà Elihu i ìdáhùn ̀rọ̀ ẹnu àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ̀̀ta wọ̀nyí nígbà náà ni ó bínú.

6 Elihu, ọmọ Barakeli, ará Busi, dáhùn ó ,

"Ọmọdé ni èmi,

àgbà ̀yin;

ǹjẹ́ nítorí náà mo dúró,

mo ń bẹ̀láti fi ìmọ̀ mi hàn yin.

7 Èmi ọjọ́ orí ni ìbá sọ̀rọ̀,

àti ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ìbá kọ́ ni ọgbọ́n.

8 Ṣùgbọ́n ̀kan ó nínú ènìyàn

àti ìmísí Olódùmarè ì máa fún wọn òye.

9 Ènìyàn ńlá ńlá í ṣe ọlọ́gbọ́n,

bẹ́̀ ni àwọn àgbà òye ̀tọ́ .

10 "Nítorí náà èmí ṣe , dẹtí sílẹ̀ mi;

èmí pẹ̀yóò fi ìmọ̀ mi hàn.

11 Kíyèsi i, èmí ti dúró de ̀rọ̀ yín;

èmi fetísí àròyé yín,

nígbà ̀yin ń ̀rọ̀ ti ̀yin yóò sọ;

12 àní, mo fiyèsí yín tinútinú.

kíyèsi i, ẹnìkan nínú yín ó le Jobu irọ́;

tàbí ó a lóhùn àríyànjiyàn rẹ̀!

13 ̀yin ó ṣe , Àwa ọgbọ́n àwárí;

Ọlọ́run ni ó í ṣubú í ṣe ènìyàn.

14 òun ti sọ̀rọ̀ mi,

bẹ́̀ ni èmi yóò fi ̀rọ̀ yín a lóhùn.

15 "Ẹnu wọ́n, wọn dáhùn mọ́,

wọ́n ṣíwọ́ ̀rọ̀ í sọ.

16 Mo retí, nítorí wọn fọhùn, wọ́n dákẹ́ jẹ́́;

wọn dáhùn mọ́.

17 Bẹ́̀ ni èmí ó dáhùn nípa ti èmi,

èmí pẹ̀yóò fi ìmọ̀ mi hàn.

18 Nítorí èmi kún fún ̀rọ̀ sísọ,

̀ń rọ̀ mi ni inú mi.

19 Kíyèsi i, ikùn mi dàbí ọtí wáìnì, ojú-ìhò;

ó múra tán láti bẹ́ ìgò-awọ tuntun.

20 Èmí ó sọ, ara ó le rọ̀ ,

èmí ó ètè mi, èmí ó dáhùn.

21 Lóòtítọ́ èmi yóò ṣe ojúsàájú ẹnìkankan,

bẹ́̀ ni èmí yóò ṣe ìpọ́nni fún ẹnìkan.

22 Nítorí èmí mọ̀ ̀rọ̀ ìpọ́nni í sọ ṣíṣe bẹ́̀,

ẹlẹ́dàá mi yóò mi kúrò lọ́gán.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-