Publicidade

2 Reis 6

Orí àáké lójú omi

1 Àwọn ọmọ wòlíì sọ fún Eliṣa , "ó, ibi a ti pàdé pẹ̀rẹ, ó kéré fún wa. 2 Jẹ́ àwa ó lọ Jordani, ibi ẹnìkọ̀̀kan ti le ̀kan, jẹ́ àwa ó kọ́síbẹ̀ fún wa láti gbé."

Ó , "Lọ."

3 Nígbà náà ni ̀kan lára wọn , "ó ́, èmí bẹ̀ ́, láti àwọn ìránṣẹ́ rẹ lọ?"

Eliṣa a lóhùn , "Èmi yóò lọ," 4 Ó lọ pẹ̀wọn.

Wọ́n lọ Jordani wọ́n bẹ̀rẹ̀ igi. 5 ̀kan ṣe igi náà, àáké irin náà bọ́ sínú omi, ó kígbe sókè , "O! Olúwa mi, mo a ni!"

6 Ènìyàn Ọlọ́run béèrè , "Níbo ni ó bọ́ ?" Nígbà ó fi ibẹ̀ hàn án, Eliṣa igi kan ó ú síbẹ̀, ó irin náà lójú omi. 7 Ó , "Gbé e jáde." Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà na ọwọ́ rẹ̀ jáde ó un.

8 Nísinsin yìí ọba Aramu ogun pẹ̀Israẹli ó àwọn ìránṣẹ́ rẹ gbèrò, ó , "Èmi yóò ṣe ibùdó mi ibí yìí nínú èyí náà àti ibí yìí."

9 Ènìyàn Ọlọ́run rán iṣẹ́ ọba Israẹli , "Kíyèsi ara láti kọjá ibẹ̀ yẹn, nítorí ará Aramu wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ síbẹ̀." 10 Bẹ́̀ ni ọba Israẹli wo ibi ènìyàn Ọlọ́run náà fihàn, ̀̀kan i Eliṣa kìlọ̀ fún ọba, bẹ́̀ ni ó lórí sísọ ibẹ̀.

11 Èyí ọba Aramu bínú. Ó pe àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ṣé ìwọ sọ fún mi èwo nínú wa ni ó ̀gbẹ́ ọba Israẹli?"

12 ̀kan lára ìránṣẹ́ rẹ̀ , "̀kan nínú wa, olúwa ọba mi, ṣùgbọ́n Eliṣa, wòlíì ó Israẹli, sọ fún ọba Israẹli ̀rọ̀ gangan ó sọ nínú yàrá rẹ̀."

13 Ọba pa á láṣẹ, "Lọ, lọ wo ibi ó , èmi ó rán ènìyàn láti lọ un ." Ìròyìn padà , "Ó Dotani." 14 Nígbà náà ni ó rán àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ àti ogun ńlá ó le síbẹ̀. Wọ́n lọ alẹ́ wọ́n ìlú náà .

15 Nígbà ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run dìde ó jáde lọ òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, ogun pẹ̀ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ wọn ti ìlú náà . "è, olúwa mi! ni àwa ó ṣe?" ìránṣẹ́ náà béèrè.

16 "ṣe bẹ̀," wòlíì náà dáhùn, "Àwọn ó pẹ̀wa, wọ́n pọ̀ ju àwọn ó pẹ̀wọn lọ."

17 Eliṣa gbàdúrà, "Olúwa, la ojú rẹ̀ ó ba à ríran." Nígbà náà Olúwa la ojú ìránṣẹ́ náà, ó , ó òkè ńlá ó kún fún ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ iná gbogbo Eliṣa .

18 àwọn ̀ṣe ń sọ̀kalẹ̀ níwájú rẹ, Eliṣa gbàdúrà Olúwa . "Bu ìfọ́lu àwọn ènìyàn wọ̀nyí," Olúwa ṣe gẹ́gẹ́ Eliṣa ti béèrè.

19 Eliṣa sọ fún wọn , "Èyí í ṣe ̀bẹ́̀ ni èyí í ṣe ìlú náà. Tẹ̀mi, èmi yóò u yín lọ ̀dọ̀ ọkùnrin ̀yin ń ." Ó sìn wọ́n lọ Samaria.

20 Lẹ́yìn ìgbà wọ́n wọ ìlú náà, Eliṣa , "Olúwa, la ojú àwọn ọkùnrin wọ̀nyí wọn ó ríran." Nígbà náà Olúwa la ojú wọn, wọ́n ríran, wọ́n níbẹ̀, nínú Samaria.

21 Nígbà ọba Israẹli wọn, ó béèrè lọ́wọ́ Eliṣa , "Ṣé èmi ó pa wọ́n, baba mi? Ṣé èmi ó pa wọ́n?"

22 "ṣe pa wọ́n," ó dáhùn. "Ṣé ìwọ yóò pa àwọn ọkùnrin ìwọ pẹ̀idà rẹ tàbí ọrun rẹ? Gbé oúnjẹ àti omi síwájú wọn wọn ó jẹ wọn mu, nígbà náà wọn padà lọ ̀dọ̀ ̀wọn." 23 Bẹ́̀ ni ó pèsè àsè ńlá fún wọn, lẹ́yìn ìgbà wọ́n jẹ wọ́n mu, ó rán wọn lọ, wọ́n padà ̀dọ̀ ̀wọn. Bẹ́̀ ni ẹgbẹ́ láti Aramu dáwọ́ ìgbógunti ilẹ̀ Israẹli dúró.

Ìyàn Samaria

24 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ni Beni-Hadadi ọba Aramu gbogbo àwọn ogun rẹ̀ jọ wọ́n yan sókè wọ́n dúró ti Samaria. 25 Ìyàn ńlá ìlú Samaria; wọ́n dúró ì bẹ́̀ a fi ń ta orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan ọgọ́rùn-ún ìwọ̀n fàdákà àti ìdámẹ́rin òsùwọ̀n kábù imí ẹyẹlé, fún ìwọ̀n fàdákà márùn-ún.

26 Gẹ́gẹ́ ọba Israẹli ti ń kọjá lọ lórí odi, obìnrin kan sọkún i , "Ràn lọ́wọ́, olúwa ọba mi!"

27 Ọba a lóhùn , "Olúwa gbà ́, níbo ni èmi yóò gbé ti gbà ́? Láti inú ilẹ̀ ìpakà, tàbí láti inú ibi ìfúntí?" 28 Nígbà náà ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà , "ni ó ṣẹlẹ̀?"

Obìnrin náà dáhùn , "Obìnrin yìí fún mi , ọmọkùnrin rẹ àwa ó jẹ ́ lónìí, ̀la àwa yóò jẹ ọmọkùnrin tèmi.29 Bẹ́̀ ni a ṣe ọmọkùnrin mi a jẹ ́. ọjọ́ kejì mo fún un , ọmọkùnrin rẹ àwa ó jẹ,ṣùgbọ́n ó ti gbé e pamọ́."

30 Nígbà ọba gbọ́ ̀rọ̀ obìnrin náà, ó fa aṣọ rẹ̀ ya. Gẹ́gẹ́ ó ti ń kọjá lọ orí odi, àwọn ènìyàn ó níbẹ̀ abẹ́, ó aṣọ ̀fọ̀ ara rẹ̀. 31 Ó , "Ọlọ́run ó fi ìyà jẹ , àti bẹ́̀ lọ dájúdájú, orí ọmọkùnrin Eliṣa ọmọ Ṣafati ó ọrùn rẹ̀ òní!"

32 Nísinsin yìí Eliṣa jókòó ilé rẹ̀ àwọn àgbàgbà náà jókòó pẹ̀rẹ̀. Ọba rán oníṣẹ́ síwájú rẹ̀, ṣùgbọ́n ó ibẹ̀, Eliṣa sọ fún àwọn àgbàgbà , "Ṣé ̀yin apànìyàn ti ń rán ẹnìkan láti orí mi kúrò? ó, nígbà ìránṣẹ́ náà , ti ìlẹ̀kùn dìímú ṣinṣin ẹnu-ọ̀, ìró ẹsẹ̀ olúwa rẹ̀ ha lẹ́yìn rẹ?"

33 Nígbà ó ń sọ̀rọ̀ wọn, ìránṣẹ́ náà sọ̀kalẹ̀ a. Ọba náà , "Ibi yìí láti ̀dọ̀ Olúwa ni. ni ó èmi yóò fi dúró de Olúwa i?"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-