Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuel 13

Amnoni àti Tamari

1 Ó ṣe, lẹ́yìn èyí, Absalomu ọmọ Dafidi àbúrò obìnrin kan ó ṣe arẹwà, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Tamari; Amnoni ọmọ Dafidi fẹ́ràn rẹ̀.

2 Amnoni banújẹ́ títí ó fi ṣe àìsàn nítorí Tamari àbúrò rẹ̀ obìnrin; nítorí wúńdíá ni; ó ṣe ohun ó ṣòro lójú Amnoni láti a dàpọ̀.

3 Ṣùgbọ́n Amnoni ̀rẹ́ kan, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Jonadabu, ọmọ Ṣimea ̀gbọ́n Dafidi, Jonadabu jẹ́ alárékérekè ènìyàn gidigidi. 4 Ó fún un , "Èéṣe ìwọ ọmọ ọba ń fi ń lójoojúmọ́ báyìí? Ǹjẹ́ o sọ fún mi?"

Amnoni fún un , "Èmi fẹ́ Tamari àbúrò Absalomu arákùnrin mi."

5 Jonadabu fún un , "Dùbúlẹ̀ ibùsùn rẹ ìwọ díbọ́n , ìwọ sàn, baba rẹ yóò ́, ìwọ ó fún un , Jọ̀wọ́ jẹ́ Tamari àbúrò mi ó fún mi oúnjẹ ó ṣe oúnjẹ náà níwájú mi èmi ó i, èmi ó jẹ ́ ọwọ́ rẹ̀.’ "

6 Amnoni dùbúlẹ̀, ó díbọ́n òun ṣàìsàn, ọba ó, Amnoni fún ọba , "Jọ̀wọ́, jẹ́ Tamari àbúrò mi ó , ó dín àkàrà méjì lójú mi, èmi ó jẹ ọwọ́ rẹ̀."

7 Dafidi ránṣẹ́ Tamari ilé , "Lọ ilé Amnoni ̀gbọ́n rẹ, ó se oúnjẹ fún un." 8 Tamari lọ ilé Amnoni ̀gbọ́n rẹ̀, òun ń bẹ ìdùbúlẹ̀. Tamari ìyẹ̀fun, ó ó, ó fi ṣe àkàrà lójú rẹ̀, ó dín àkàrà náà. 9 Òun àwo náà, ó á sínú àwo mìíràn níwájú rẹ̀; ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti jẹ.

Amnoni , "Jẹ́ gbogbo ọkùnrin jáde kúrò lọ́dọ̀ mi!" Wọ́n jáde olúkúlùkù ọkùnrin kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀. 10 Amnoni fún Tamari , "oúnjẹ náà yàrá, èmi ó jẹ ́ lọ́wọ́ rẹ." Tamari àkàrà ó ṣe, ó un tọ Amnoni ̀gbọ́n rẹ̀ yàrá. 11 Nígbà ó súnmọ́ ọn láti fi oúnjẹ fún un, òun dìímú, ó fún un , "dùbúlẹ̀ , àbúrò mi."

12 Òun a lóhùn , "Bẹ́̀ kọ́ ̀gbọ́n mi, ṣe tẹ́ mi; nítorí tọ a ṣe irú nǹkan bẹ́̀ Israẹli, ìwọ ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí. 13 Àti èmi, níbo ni èmi ó gbé ìtìjú mi wọ̀? Ìwọ ó dàbí ̀kan nínú àwọn aṣiwèrè Israẹli. Ǹjẹ́ nítorí náà, èmi bẹ̀ ́, sọ fún ọba; nítorí òun yóò kọ̀ láti fi fún ." 14 Ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti gbọ́ ohùn rẹ̀; ó fi agbára un, ó ṣẹ́gun rẹ̀, ó a dàpọ̀.

15 Amnoni kórìíra rẹ̀ gidigidi, ìríra náà ju ìfẹ́ òun ti i lọ. Amnoni fún un , "Dìde, o máa lọ!"

16 Òun fún un , "ha ìdí ! Lílé ìwọ ń mi yìí burú ju èyí ìwọ ti ṣe mi lọ."

Ṣùgbọ́n òun fẹ́ gbọ́ tirẹ̀. 17 Òun pe ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ í ṣe ìránṣẹ́ rẹ̀, ó fún un , "Jọ̀wọ́, ti obìnrin yìí sóde fún mi, o ti ìlẹ̀kùn mọ́ ọn." 18 Òun aṣọ aláràbarà kan lára rẹ̀, nítorí irú aṣọ àwọ̀lékè bẹ́̀ ni àwọn ọmọbìnrin ọba í ṣe wúńdíá máa ń wọ̀. Ìránṣẹ́ rẹ̀ un jáde, ó ti ìlẹ̀kùn mọ́ ọn. 19 Tamari bu eérú orí rẹ̀, ó fa aṣọ aláràbarà ń bẹ lára rẹ̀ ya, ó ọwọ́ rẹ̀ orí, ó ń kígbe ó ti ń lọ.

Absalomu kọlu Amnoni

20 Absalomu ̀gbọ́n rẹ̀ i léèrè , "Amnoni ̀gbọ́n rẹ sùn ? Ǹjẹ́ àbúrò mi, dákẹ́; ̀gbọ́n rẹ í ṣe; fi nǹkan yìí ọkàn rẹ." Tamari jókòó ìbànújẹ́ ilé Absalomu ̀gbọ́n rẹ̀.

21 Ṣùgbọ́n nígbà Dafidi ọba gbọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi. 22 Absalomu Amnoni sọ nǹkan rere, tàbí búburú, nítorí Absalomu kórìíra Amnoni nítorí èyí ó ṣe, àní ó fi agbára Tamari àbúrò rẹ̀.

23 Ó ṣe, lẹ́yìn ọdún méjì, Absalomu olùrẹ́run àgùntàn Baali-Hasori, èyí ó gbé Efraimu, Absalomu pe gbogbo àwọn ọmọ ọba. 24 Absalomu tọ ọba , ó , "ó, jọ̀wọ́, ìránṣẹ́ rẹ olùrẹ́run àgùntàn, èmi bẹ̀ ́, jẹ́ ọba, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ lọ."

25 Ọba fún Absalomu , "Bẹ́̀ kọ, ọmọ mi, mo bẹ̀ ́, ṣe jẹ́ gbogbo wa lọ, a à náwó púpọ̀." Ó rọ̀ ́ gidigidi, ṣùgbọ́n òun fẹ́ lọ, òun súre fún un.

26 Absalomu , "le bẹ́̀, èmi bẹ̀ ́, jẹ́ Amnoni ̀gbọ́n mi wa lọ."

Ọba , "Ìdí rẹ̀ yóò fi lọ." 27 Absalomu rọ̀ ́, òun jẹ́ Amnoni àti gbogbo àwọn ọmọ ọba a lọ.

28 Absalomu fi àṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "̀yin máa kíyèsi àkókò ọtí-wáinì yóò ọkàn Amnoni dùn, èmi ó fún yín , Kọlu Amnoni,pa á. bẹ̀. Ṣé èmi ni ó fi àṣẹ fún yin? ṣe gírí, ṣe alágbára ọmọ." 29 Àwọn ìránṣẹ́ Absalomu ṣe Amnoni gẹ́gẹ́ Absalomu ti pàṣẹ. Gbogbo àwọn ọmọ ọba dìde, olúkúlùkù gun ìbáaka rẹ̀, wọ́n .

30 Nígbà wọ́n ń bẹ lọ́, ìròyìn ̀dọ̀ Dafidi , "Absalomu pa gbogbo àwọn ọmọ ọba, ̀kan nínú wọn." 31 Ọba dìde, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó dùbúlẹ̀ ni ilẹ̀; gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wọ́n dúró í aṣọ wọn ya.

32 Jonadabu ọmọ Ṣimea arákùnrin Dafidi dáhùn ó , "olúwa mi ọba ṣe wọ́n ti pa gbogbo àwọn ̀dọ́mọdékùnrin àwọn ọmọ ọba; nítorí Amnoni nìkan ṣoṣo ni ó , nítorí láti ẹnu Absalomu ni a ti pinnu rẹ̀ láti ọjọ́ ó ti fi agbára Tamari àbúrò rẹ̀. 33 Ǹjẹ́ olúwa mi ọba ṣe fi nǹkan yìí ọkàn gbogbo àwọn ọmọ ọba ni o , nítorí Amnoni nìkan ṣoṣo ni ó ."

Absalomu sálọ Geṣuri

34 Absalomu .

̀dọ́mọkùnrin náà ti ń ṣọ́gbé ojú rẹ̀ sókè, o si i , "̀pọ̀ ènìyàn ń bọ́ lọ́lẹ́yìn rẹ̀ láti ìhà òkè ."

35 Jonadabu fún ọba , "ó, àwọn ọmọ ọba ń bọ́; gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀, bẹ́̀ ni ó ."

36 Nígbà ó parí ̀rọ̀ ó ń sọ, ó àwọn ọmọ ọba , wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sọkún, ọba àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀sọkún ńlá ńlá.

37 Absalomu , ó tọ Talmai lọ, ọmọ Ammihudu, ọba Geṣuri. Dafidi ń káàánú nítorí ọmọ rẹ̀ lójoojúmọ́.

38 Absalomu , ó lọ Geṣuri ó gbé ibẹ̀ lọ́dún mẹ́ta. 39 Ọkàn Dafidi ọba gidigidi Absalomu, nítorí ó gba ìpẹ̀ ti Amnoni: ó à ti .

Veja também