Publicidade

2 Samuel 9

Dafidi àti Mefiboṣeti

1 Dafidi béèrè , ̀kan nínú àwọn ẹni ń ṣe ìdílé Saulu síbẹ̀ ? èmi ṣe oore fún un nítorí Jonatani.

2 Ìránṣẹ́ kan ti ìdílé Saulu, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣiba, wọ́n é sọ́dọ̀ Dafidi, ọba béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Ìwọ ni Ṣiba ?"

Ó dáhùn , "Ìránṣẹ́ rẹ ni."

3 Ọba , "ha ̀kan nínú ìdílé Saulu síbẹ̀, èmi ṣe oore Ọlọ́run fún un?"

Ṣiba fún ọba , "Jonatani ọmọ kan síbẹ̀ ya arọ."

4 Ọba fún un , "Níbo ni ó gbé ?"

Ṣiba fún ọba , "ó, òun ilé Makiri, ọmọ Ammieli, Lo-Debari."

5 Dafidi ọba ránṣẹ́, ó un láti ilé Makiri ọmọ Ammieli láti Lo-Debari .

6 Mefiboṣeti ọmọ Jonatani ọmọ Saulu tọ Dafidi , ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó ọlá fún un.

Dafidi , "Mefiboṣeti!"

Òun dáhùn , "ó, ìránṣẹ́ rẹ!"

7 Dafidi fún un , "ṣe bẹ̀, nítorí nítòótọ́ èmi ó ṣe oore fún nítorí Jonatani baba rẹ, èmi ó tún fi gbogbo ilé Saulu baba rẹ fún , ìwọ ó máa mi jẹun nígbà gbogbo ibi oúnjẹ mi."

8 Mefiboṣeti tẹríba, ó , "ni ìránṣẹ́ rẹ jásí, ìwọ ó fi máa wo òkú ajá èmi."

9 Ọba pe Ṣiba ìránṣẹ́ Saulu, ó fún un , "Gbogbo nǹkan í ṣe ti Saulu, àti gbogbo èyí í ṣe ti ìdílé rẹ̀ ni èmi fi fún ọmọ olúwa rẹ. 10 Ìwọ, àti àwọn ọmọ rẹ, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ ni yóò máa ro ilẹ̀ náà fún un, ìwọ ni yóò máa ìkórè , ọmọ olúwa rẹ yóò máa oúnjẹ jẹ, ṣùgbọ́n Mefiboṣeti ọmọ olúwa rẹ yóò máa mi jẹun nígbà gbogbo ibi oúnjẹ mi." (Ṣiba ọmọ mẹ́̀́dógún àti ogún ìránṣẹ́kùnrin.)

11 Ṣiba fún ọba , "Gẹ́gẹ́ gbogbo èyí olúwa mi ọba ti pàṣẹ fún ìránṣẹ́ rẹ, bẹ́̀ náà ni ìránṣẹ́ rẹ ó ṣe." Ọba , "ti Mefiboṣeti, yóò máa jẹun ibi oúnjẹ mi, gẹ́gẹ́ ̀kan nínú àwọn ọmọ ọba."

12 Mefiboṣeti ọmọ kékeré kan, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika. Gbogbo àwọn ń gbé ilé Ṣiba ni ó ń ṣe ìránṣẹ́ fún Mefiboṣeti. 13 Mefiboṣeti ń gbé Jerusalẹmu, òun a máa jẹun nígbà gbogbo ibi oúnjẹ ọba; òun yarọ ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-