Publicidade

Êxodo 14

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli wọn padà sẹ́yìn, wọ́n pàgọ́ tòsí Pi-Hahirotu láàrín Migdoli òun Òkun, wọn ó pàgọ́ ̀Òkun, òdìkejì Baali-Ṣefoni. 3 Farao yóò ronú àwọn ọmọ Israẹli ń ráre káàkiri ìdààmú ni àti aginjù náà ti wọn mọ́. 4 Èmi yóò ọkàn Farao le ti yóò fi lépa wọn. Ṣùgbọ́n èmi yóò gba ògo fún ará mi láti ìpàṣẹ Farao àti ogun rẹ̀, àti àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ Èmi ni Olúwa." Àwọn Israẹli ṣe bẹ́̀.

5 Nígbà wọ́n sọ fún ọba Ejibiti àwọn ènìyàn náà ti sálọ, ọkàn Farao àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ padà àwọn ènìyàn, wọ́n , "ni ohun àwa ṣe yìí? Àwa ti jẹ́ àwọn ọmọ Israẹli ó lọ, a ti pàdánù ìsìnrú wọn." 6 Ó di kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀, ó àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ pẹ̀rẹ̀, 7 ó ẹgbẹ̀ta (600) ọmọ-ogun oníkẹ̀kẹ́ ó jáfáfá jùlọ àti gbogbo ọmọ-ogun oníkẹ̀kẹ́ mìíràn Ejibiti, olórí fún olúkúlùkù wọn. 8 Olúwa ọkàn Farao ọba Ejibiti le, ó bẹ̀rẹ̀ lépa àwọn ọmọ Israẹli ti ń jáde lọ àìbẹ̀. 9 Àwọn ará Ejibiti ń lépa wọn pẹ̀gbogbo ẹṣin kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀, wọ́n wọn ni ibi wọ́n pa àgọ́ lẹ́bàá òkun ìhà Pi-Hahirotu, ni òdìkejì Baali-Ṣefoni.

10 Farao ti súnmọ́ tòsí ̀dọ̀ wọn, àwọn ọmọ Israẹli gbé ojú wọn sókè, wọn àwọn ará Ejibiti súnmọ́ wọn. ̀ńlá àwọn ará Israẹli, wọ́n kígbe sókè Olúwa. 11 Wọ́n sọ fún Mose , "Ṣe nítorí ibojì ni Ejibiti ìwọ ṣe wa láti sínú aginjù? ni èyí ìwọ ṣe wa ti ìwọ fi wa jáde láti Ejibiti ? 12 Ǹjẹ́ èyí kọ́ ni àwa sọ fún ni Ejibiti, Fi sílẹ̀, jẹ́ àwa máa sin ará Ejibiti? Nítorí sàn fún wa a sin àwọn ará Ejibiti ju a sínú aginjù yìí lọ!"

13 Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà , "bẹ̀, dúró ṣinṣin ìdáǹdè Olúwa yóò fi fún un yín lónìí, àwọn ará Ejibiti ti ̀yin lónìí ni ni tún padà wọn mọ́. 14 Olúwa yóò fún un yín; ̀yin ó à mu sùúrù."

15 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Èéṣe ìwọ fi ń ? Sọ fún àwọn ará Israẹli wọn máa tẹ̀síwájú. 16 Ṣùgbọ́n, gbé ̀rẹ̀ sókè, o na ọwọ́ rẹ orí omi Òkun, ó pín àwọn ọmọ Israẹli la òkun kọjá ni orí ìyàngbẹ ilẹ̀. 17 Nígbà náà ni èmi yóò ọkàn àwọn ará Ejibiti le, wọn yóò máa lépa wọn; Èmi yóò gba ògo fún ara mi lórí Farao; lórí gbogbo ogun rẹ̀, lórí kẹ̀kẹ́ ogun àti lórí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀. 18 Àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ Èmi ni Olúwa nígbà ti èmi gba ògo fún ara mi lórí Farao: lórí kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ àti lórí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀."

19 Nígbà náà ni angẹli Ọlọ́run ti ń ṣáájú ogun Israẹli lọ, padà o rìn ni ̀yìn wọn; Òpó ìkùùkuu ń rìn ni iwájú wọn padà í rìn ni ̀yìn wọn. 20 Ó láàrín àwọn ọmọ-ogun Ejibiti àti Israẹli. Ìkùùkuu ṣú òkùnkùn àwọn ará Ejibiti ni òru náà. Ṣùgbọ́n ó tan ìmọ́lẹ̀ àwọn Israẹli ni òru náà, ̀kan súnmọ́ èkejì ni gbogbo òru náà.

21 Nígbà náà ni Mose na ọwọ́ rẹ̀ orí Òkun, ni gbogbo òru náà ni Olúwa fi òkun sẹ́yìn pẹ̀ìjì líle láti ìlà-oòrùn , ó sọ ́ di ìyàngbẹ ilẹ̀. Omi òkun pínyà, 22 àwọn ọmọ Israẹli la ìyàngbẹ ilẹ̀ kọjá nínú òkun pẹ̀ògiri omi ̀tún àti òsì.

23 Àwọn ará Ejibiti ń lépa wọn, gbogbo ẹṣin Farao, kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ wọ́ tọ̀ wọ́n lọ sínú òkun. 24 ìṣọ́ òwúrọ̀ Olúwa bojú wo ogun àwọn ará Ejibiti láàrín ̀wọ̀n iná àti ìkùùkuu, ó ìpayà àwọn ọmọ-ogun Ejibiti. 25 Ó yọ àgbá ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun wọn ó à le ṣòro fún wọn láti fi kẹ̀kẹ́ ogun náà rìn. Àwọn ará Ejibiti , "jẹ́ a àsálà kúrò iwájú àwọn ará Israẹli nítorí Olúwa ń wa nítorí wọn."

26 Olúwa fún Mose , "Na ọwọ́ rẹ orí òkun omi òkun ya padà sórí àwọn ará Ejibiti, kẹ̀kẹ́ ogun wọn àti sórí ẹlẹ́ṣin wọn." 27 Mose na ọwọ́ rẹ̀ orí òkun, òkun padà bọ́ ipò rẹ̀ nígbà ti ilẹ̀ mọ́. Àwọn ará Ejibiti ń fún omi òkun, Olúwa gbá wọn sínú òkun. 28 Omi òkun ya padà, ó bo kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin: àní, gbogbo ọmọ-ogun Farao tiwọn wọ inú òkun tọ àwọn ọmọ Israẹli lọ ̀kan nínú wọn ó .

29 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli la òkun kọjá lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ pẹ̀ògiri omi ni ̀tún àti òsì wọn. 30 Ni ọjọ́ yìí ni Olúwa gba Israẹli kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti; Israẹli òkú àwọn ará Ejibiti ni etí òkun. 31 Nígbà ti àwọn ọmọ Israẹli iṣẹ́ ìyanu ńlá ti Olúwa ṣe fún wọn lára àwọn ará Ejibiti, àwọn ènìyàn bẹ̀Olúwa, wọ́n gba Olúwa àti Mose ìránṣẹ́ rẹ gbọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-