Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 16

Hagari àti Iṣmaeli

1 Sarai, aya Abramu bímọ fún un, ṣùgbọ́n ó ọmọ ̀dọ̀ obìnrin ará Ejibiti kan ń jẹ́ Hagari. 2 Nítorí náà, Sarai fún Abramu , "Kíyèsi i Olúwa ti mi inú, èmi bímọ, wọlé tọ ọmọ ̀dọ̀ mi lọ, bóyá èmi yóò le ti ipasẹ̀ rẹ̀ ọmọ."

Abramu gba ohun Sarai sọ. 3 Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá Abramu ti ń gbé ni Kenaani ni Sarai ọmọbìnrin, ọmọ ̀dọ̀ rẹ Hagari, í ṣe ará Ejibiti fún Abramu ọkọ rẹ̀ láti fi ṣe aya.

Veja também