Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 4

12 ìwọ ro ilẹ̀, ilẹ̀ yóò fi agbára rẹ̀ so èso rẹ̀ fún mọ́. Ìwọ yóò jẹ́ ìsáǹsá àti alárìnkiri ni orí ilẹ̀ ayé."

13 Kaini fún Olúwa , "Ẹrù ìyà ̀ṣẹ̀ mi pọ̀ ju èyí mo le lọ. 14 Lónìí, ìwọ mi kúrò lórí ilẹ̀, di ẹni ó fi ara pamọ́ kúrò ojú rẹ, èmi yóò di ìsáǹsá àti alárìnkiri ayé, ẹnikẹ́ni ó mi, yóò pa ."

15 Ṣùgbọ́n, Olúwa fún , "Bẹ́̀ kọ́, ẹnikẹ́ni pa Kaini, èmi yóò gbẹ̀san ara onítọ̀hún ìgbà méje." Nígbà náà ni Ọlọ́run fi àmì ara Kaini, ẹnikẹ́ni ó ri ba à pa á. 16 Kaini kúrò níwájú Olúwa, ó ń gbé ilẹ̀ Nodi ìhà ìlà-oòrùn Edeni.

Veja também