Publicidade

Gênesis 7

1 Nígbà náà ni Olúwa fún Noa , "Wọ inú ọkọ̀ lọ ìwọ àti gbogbo ìdílé rẹ, nítorí ìwọ nìkan ni mo olódodo nínú ìran yìí. 2 méje méje nínú àwọn ẹran ó mọ́, akọ àti abo, méjì méjì takọ tabo nínú àwọn ẹran aláìmọ́. 3 méje méje pẹ̀nínú onírúurú ẹyẹ, takọ tabo ni o wọn, wọlé sínú ọkọ̀ pẹ̀rẹ, á ba à pa wọ́n mọ́ láààyè gbogbo ayé. 4 Nítorí ọjọ́ méje ìhín, èmi yóò rọ òjò sórí ilẹ̀ fún ogójì ̀sán àti ogójì òru, èmi yóò pa gbogbo ohun alààyè mo ti run kúrò lórí ilẹ̀."

5 Noa ṣe ohun gbogbo Olúwa pàṣẹ fún un.

6 Noa jẹ́ ọmọ ẹgbẹ̀ta (600) ọdún nígbà ìkún omi sórí ilẹ̀. 7 7.7: Mt 24.38; Lk 17.27.Noa àti ìyàwó rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn aya ọmọ rẹ̀ wọ inú ọkọ láti àsálà fún ìkún omi. 8 Méjì méjì ni àwọn ẹran ó mọ́ àti aláìmọ́, ti ẹyẹ àti ti gbogbo àwọn ̀afàyàfà, 9 akọ àti abo ni wọ́n wọlé pẹ̀Noa sínú ọkọ̀ Ọlọ́run ti pàṣẹ fún Noa. 10 Lẹ́yìn ọjọ́ keje, ìkún omi ayé.

11 7.11,12: 2Pt 3.6. ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kejì, Noa ọmọ ẹgbẹ̀ta (600) ọdún, ni gbogbo ìsun ibú ya, fèrèsé ìṣàn omi ̀run ṣí sílẹ̀. 12 Òjò àrọ̀ìrọ̀rọ̀ fún ogójì ̀sán àti ogójì òru.

13 ọjọ́ ìkún omi yóò bẹ̀rẹ̀ gan an ni Noa àti Ṣemu, Hamu àti Jafeti pẹ̀aya Noa àti aya àwọn ọmọ rẹ̀ wọ inú ọkọ̀. 14 Wọ́n ẹranko igbó àti ohun ̀sìn onírúurú wọn, àwọn ̀afàyàfà àti ẹyẹ àti àwọn ohun abìyẹ́ ni onírúurú wọn. 15 Méjì méjì ni gbogbo ̀ó èémí ìyè nínú wọlé pẹ̀Noa sínú ọkọ̀. 16 Gbogbo wọ́n wọlé takọ tabo Ọlọ́run ti pàṣẹ fún Noa, Olúwa wọn mọ́ inú ọkọ̀.

17 Òjò náà rọ̀ àrọ̀ìrọ̀fún ogójì ̀sán àti ogójì òru, ọkọ̀ náà ń léfòó lórí omi, kúrò lórí ilẹ̀ omi náà ti ń pọ̀ i. 18 omi náà ti ń pọ̀ i, bẹ́̀ náà ni ọkọ̀ náà ń léfòó lójú omi. 19 Omi náà pọ̀ bẹ́̀ ó bo gbogbo àwọn òkè gíga ó lábẹ́ ̀run. 20 Omi náà kún bo àwọn òkè, ìwọ̀n ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dógún. 21 Gbogbo ohun alààyè ó lórí ilẹ̀ parun: ẹyẹ, ohun ̀sìn, ẹranko igbó, àwọn ̀afàyàfà àti ènìyàn. 22 Gbogbo ohun ó lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ èémí ìyè ihò imú wọn ni ó . 23 Gbogbo ohun alààyè ó lórí ilẹ̀ ayé ni a parẹ́: ènìyàn àti ẹranko, àwọn ohun ń rìn nílẹ̀, àwọn ẹyẹ ojú ̀run pátápátá ṣègbé. Noa àti àwọn ó pẹ̀rẹ̀ nínú ọkọ̀ ni ó ṣẹ́.

24 Omi náà bo ilẹ̀ fún àádọ́jọ ọjọ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-