Publicidade

Jó 15

Elifasi tako ọrọ̀ Jobu

1 Ìgbà náà Elifasi, ará Temani, dáhùn ,

2 "Ọlọ́gbọ́n a máa sọ̀rọ̀ ìmọ̀ asán

ó máa fi afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn kún ara rẹ̀ nínú?

3 Òun máa fi àròyé sọ̀rọ̀ èrè,

tàbí pẹ̀̀rọ̀ nínú èyí fi ṣe rere?

4 Ṣùgbọ́n ìwọ ṣá ìbẹ̀,

ìwọ iṣẹ́ ìsìn lọ́níwájú Ọlọ́run.

5 Nítorí ẹnu ara rẹ̀ ni ó jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ rẹ̀,

ìwọ yàn ahọ́n alárékérekè ni ààyò.

6 Ẹnu ara rẹ̀ ni ó lẹ́bi, í ṣe èmi;

àní ètè ara rẹ̀ ni ó jẹ́rìí gbè ́.

7 "Ìwọ ha í ṣe ọkùnrin a kọ́ ?

Tàbí a ha ṣáájú àwọn òkè?

8 Ìwọ gbúròó àṣírí Ọlọ́run ?

Tàbí ìwọ ha ọgbọ́n dúró sọ́dọ̀ ara rẹ?

9 ni ìwọ mọ̀ àwa mọ̀?

Òye ó nínú wa?

10 Àwọn arúgbó àti ògbólógbòó ènìyàn pẹ̀wa,

wọ́n dàgbà ju baba rẹ lọ.

11 Ìtùnú Ọlọ́run ha kéré lọ́dọ̀ rẹ?

̀rọ̀ kan ṣe jẹ́jẹ́ lọ́dọ̀ rẹ?

12 Èéṣe ti ọkàn rẹ fi ń ti kiri,

ni ìwọ tẹjúmọ́ tóbẹ́̀.

13 ìwọ fi ̀rẹ padà lòdì Ọlọ́run,

ó fi ń jẹ́ ki ̀rọ̀kọ́rọ̀ ó máa bọ́ ẹnu rẹ̀ bẹ́̀?

14 "ni ènìyàn ó fi jẹ mímọ́,

àti ẹni a tinú obìnrin yóò fi ṣe olódodo?

15 Kíyèsi i, bi Ọlọ́run ko ba gbẹ́kẹ̀àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀,

àní àwọn ̀run mọ́ ojú rẹ̀,

16 mélòó mélòó ni ènìyàn, ẹni ìríra àti eléèérí,

ń mu ̀ṣẹ̀ bi ẹní mu omi.

17 "Èmi ó fihàn ́, gbọ́ ti èmi;

èyí èmi , òun ni èmi ó sọ,

18 ohun àwọn ọlọ́gbọ́n ti pa ìtàn láti

̀dọ̀ àwọn baba wọn , ti wọ́n fi pamọ́.

19 Àwọn a fi ilẹ̀ ayé fún nìkan,

ti àlejò kan wọ́n kọjá.

20 Ènìyàn búburú ń ṣe làálàá,

pẹ̀ìrora, ọjọ́ rẹ̀ gbogbo,

àti iye ọdún a sílẹ̀ fún aninilára.

21 Ìró ìbẹ̀ń bẹ etí rẹ̀;

nínú ìrora ni apanirun yóò dìde i.

22 gbàgbọ́ òun ó jáde kúrò nínú òkùnkùn;

a ṣà á sápá kan fún idà.

23 Ó ń káàkiri fún oúnjẹ , níbo ó ?

Ó mọ̀ ọjọ́ òkùnkùn súnmọ́ tòsí.

24 Ìpọ́njú pẹ̀ìrora ọkàn yóò un bẹ̀,

wọ́n ó ṣẹ́gun rẹ̀ bi ọba ti ìmúra ogun.

25 Nítorí ó ti nawọ́ rẹ̀ jáde lòdì Ọlọ́run,

ó múra rẹ̀ le lòdì Olódùmarè,

26 ó súre, ó fi ̀yìn gíga,

àní fi ike-kókó àpáta rẹ̀ ó nípọn kọlù ú.

27 "Nítorí òun fi ̀rẹ̀ bo ara rẹ̀ lójú,

o ṣe ̀pọ̀lọpọ̀ ẹran ̀gbẹ́ rẹ̀.

28 Òun gbé inú ahoro ìlú,

àti nínú ilẹ̀ ènìyàn gbé mọ́,

ó múra tán láti di àlàpà.

29 Òun di ọlọ́rọ̀, bẹ́̀ ohun ìní rẹ̀

dúró pẹ́; bẹ́̀ pípé rẹ̀ dúró pẹ́ lórí ilẹ̀.

30 Òun yóò jáde kúrò nínú òkùnkùn;

̀wọ́-iná ni yóò ̀ka rẹ̀,

àti nípasẹ̀ ̀ẹnu Ọlọ́run a ó gba kúrò.

31 òun ó ṣe gbẹ́kẹ̀asán, ó ṣe tan ara rẹ̀ jẹ.

Nítorí asán yóò jásí èrè rẹ̀.

32 A ó un ṣẹ ṣáájú pípé ọjọ́ rẹ̀,

̀ka rẹ̀ yóò tutù.

33 Yóò dàbí àjàrà a gbọn èso àìpọ́n rẹ̀ dànù,

yóò rẹ̀ ìtànná rẹ̀ dànù i ti igi Olifi.

34 Nítorí ayọ̀ àwọn àgàbàgebè yóò túká,

iná yóò àgọ́ àwọn ó fẹ́ràn àbẹ̀tẹ́lẹ̀.

35 Wọ́n lóyún ìwà ìkà, wọ́n ̀ṣẹ̀,

ikùn wọn pèsè ̀tàn."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-