Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 18

Ìdáhùn Bilidadi

1 Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn, ó ,

2 "Nígbà wo ni ̀yin yóò fi ìdí ̀rọ̀ ;

ó, nígbẹ̀yìn rẹ̀ ni àwa ó máa sọ.

3 Nítorí ni a ṣe ń ẹranko,

a ń si ẹni ̀gàn ojú yín?

4 Ìwọ fa ara rẹ ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ nínú ìbínú rẹ̀;

a ha kọ ayé sílẹ̀ nítorí rẹ̀ bi?

Tàbí a àpáta kúrò ipò rẹ̀?

5 "Nítòótọ́ ìmọ́lẹ̀ ènìyàn búburú ni a ó pa kúrò,

̀wọ́-iná rẹ̀ yóò tan ìmọ́lẹ̀.

6 Ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn nínú àgọ́ rẹ̀,

fìtílà ̀gbẹ́ rẹ̀ ni a ó pa pẹ̀.

7 Ìrìn ẹsẹ̀ agbára rẹ̀ yóò di fífọ;

ète òun tìkára rẹ̀ ni yóò i ṣubú.

8 Nípa ̀ṣẹ̀ òun tìkára rẹ̀ ó ti bọ́ sínú àwọ̀n,

ó rìn lórí okùn dídẹ.

9 Tàkúté ni yóò un gìgísẹ̀,

àwọn àwọ̀n a dẹ yóò ṣẹ́gun rẹ̀.

10 A dẹkùn sílẹ̀ fún un lórí ilẹ̀,

a ̀fìn fún un lójú ̀.

11 ̀ńlá yóò á ìhà gbogbo,

yóò e ẹsẹ̀ rẹ̀.

12 Àìlera rẹ̀ yóò di púpọ̀ fún ebi,

ìparun yóò dìde dúró i nígbà ó ṣubú.

13 Yóò jẹ ̀ara rẹ̀;

ikú àkọ́ni yóò jẹ agbára rẹ̀ run.

14 A ó á tu kúrò nínú àgọ́ ó gbẹ́kẹ̀,

a ó un tọ ọba ̀ńlá lọ.

15 Yóò máa jókòó nínú àgọ́ rẹ̀ èyí í ṣe tirẹ̀;

sulfuru ti o jóná ni a ó fún káàkiri ibùgbé rẹ̀.

16 Gbòǹgbò rẹ̀ yóò gbẹ níṣàlẹ̀,

a ó ̀ka rẹ̀ kúrò lókè.

17 Ìrántí rẹ̀ yóò parun kúrò ni ayé,

yóò orúkọ rẹ̀ ìgboro ìlú.

18 A ó e láti inú ìmọ́lẹ̀ inú òkùnkùn,

a ó e kúrò ayé.

19 yóò ọmọ tàbí ọmọ ọmọ nínú àwọn ènìyàn rẹ̀,

bẹ́̀ ni ẹnikẹ́ni yóò nínú agbo ilé rẹ̀.

20 Ẹnu yóò ya àwọn ìran ti ìwọ̀-oòrùn ìgbà ọjọ́ rẹ̀,

gẹ́gẹ́ ̀ìwárìrì ti í àwọn ìran ti ìlà-oòrùn.

21 Nítòótọ́ irú bẹ́̀ ni ibùgbé àwọn

ènìyàn búburú, èyí ni ipò ẹni mọ̀ Ọlọ́run."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também