Publicidade

Jó 14

Jobu tẹ̀síwájú nínú àròyé rẹ̀

1 "Ènìyàn a nínú obìnrin,

ọlọ́jọ́ díẹ̀ ni, ó kún fún ìpọ́njú.

2 Ó jáde ìtànná ewéko, a e lulẹ̀;

ó ń lọ òjìji, dúró pẹ́.

3 Ìwọ ń síjú rẹ irú èyí ni?

Ìwọ mi sínú ìdájọ́ pẹ̀rẹ?

4 Ta ni ó ohun mímọ́ láti inú àìmọ́ jáde ?

ẹnìkan!

5 Ǹjẹ́ a ti pinnu ọjọ́ rẹ̀,

iye oṣù rẹ̀ ń bẹ ọwọ́ rẹ,

ìwọ ti pààlà rẹ̀, bẹ́̀ òun le kọjá rẹ̀.

6 Yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, ó sinmi,

títí yóò fi ọjọ́ rẹ̀ alágbàṣe.

7 "Nítorí ìrètí fún igi, a

e lulẹ̀, yóò tún sọ,

àti ̀ka rẹ̀ tuntun yóò gbẹ.

8 gbòǹgbò rẹ̀ tilẹ̀ di ogbó nínú ilẹ̀,

kùkùté rẹ̀ si ni ilẹ̀,

9 síbẹ̀ nígbà ó gbóòórùn omi,

yóò sọ, yóò yọ ̀ka jáde irúgbìn.

10 Ṣùgbọ́n ènìyàn , a dàánù,

àní ènìyàn jọ̀wọ́ ̀rẹ̀ lọ́wọ́: Òun mọ́.

Àgékúrú ọjọ́ ọmọ ènìyàn

11 "omi ti í tán nínú ipa odò,

àti odò ṣì í gbẹ,

12 bẹ́̀ ni ènìyàn dùbúlẹ̀ dìde mọ́;

títí ̀run yóò fi mọ́,

wọ́n yóò , a yóò wọn kúrò lójú oorun wọn.

13 "Háà! ìwọ ìbá fi pamọ́ ipò òkú,

ìwọ ó fi pamọ́ ìkọ̀kọ̀,

títí ìbínú rẹ yóò fi rékọjá,

ìwọ ìbá lànà ìgbà kan sílẹ̀ fún mi, ó si rántí mi!

14 ènìyàn yóò tún ?

Gbogbo ọjọ́ ìgbà a sílẹ̀

fún mi ni èmi dúró , títí àmúdọ̀tún mi yóò fi .

15 Ìwọ ìbá , èmi ìbá lóhùn;

ìwọ ó ìfẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

16 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ń kaye ìṣísẹ̀ mi;

ìwọ fa ọwọ́ rẹ kúrò nítorí ̀ṣẹ̀ mi?

17 A fi èdìdì di ìrékọjá mi sínú àpò,

ìwọ rán àìṣedéédéé mi pọ̀.

18 "Àti nítòótọ́ òkè ńlá ó ṣubú, ó dasán,

a ṣí àpáta kúrò ipò rẹ̀.

19 Omi a máa yinrin òkúta, ìwọ a

omi sàn bo ohun ó jáde lórí ilẹ̀,

ìwọ sọ ìrètí ènìyàn òfo.

20 Ìwọ ṣẹ́gun rẹ̀ láéláé, òun kọjá lọ!

Ìwọ pa awọ ojú rẹ̀ , o rán an lọ kúrò.

21 Àwọn ọmọ rẹ̀ bọ́ ipò ọlá, òun mọ̀;

wọ́n rẹ̀ sílẹ̀, òun kíyèsi i lára wọn.

22 Ṣùgbọ́n ẹran-ara rẹ̀ ni yóò ìrora

ọkàn rẹ̀ ni yóò máa ìbìnújẹ́ nínú rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-