Publicidade

Jó 42

Ìrònúpìwàdà Jobu

1 Nígbà náà Jobu Olúwa lóhùn, ó ,

2 "Èmi mọ̀ , ìwọ e ṣe ohun gbogbo,

àti , si ìrò inú a fa sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ.

3 Ìwọ béèrè, ta ni ẹni ń fi ìgbìmọ̀ pamọ́ láìní ìmọ̀?

Nítorí náà èmi ṣe ń sọ èyí èmi mọ̀,

ohun ó ṣe ìyanu jọjọ níwájú mi, ti èmi mòye.

4 "Ìwọ , Gbọ́ tèmi báyìí,

èmi ó sọ; èmi ó béèrè lọ́wọ́ rẹ,

ìwọ yóò mi lóhùn.

5 Etí mi ti gbọ́ nípa rẹ,

ṣùgbọ́n nísinsin yìí ojú mi ti .

6 Ǹjẹ́ nítorí náà èmi kórìíra ara mi,

mo ronúpìwàdà nínú ekuru àti eérú."

Ọlọ́run bùkún Jobu

7 Bẹ́̀ ó , lẹ́yìn ìgbà Olúwa ti sọ ̀rọ̀ wọ̀nyí fún Jobu, Olúwa fún Elifasi, ará Temani , mo bínú , àti àwọn ̀rẹ́ rẹ méjèèjì, nítorí ̀yin sọ̀rọ̀, ti èmi, ohun ó tọ́, Jobu ìránṣẹ́ mi ti sọ. 8 Nítorí náà, akọ ẹgbọrọ màlúù méje, àti àgbò méje, tọ̀ Jobu ìránṣẹ́ mi lọ, fi ẹbọ sísun fún ara yín; Jobu ìránṣẹ́ mi yóò gbàdúrà fún yin; nítorí àdúrà rẹ̀ èmi yóò gbà; èmi ó ba ṣe si yín ìṣìnà yín, ti ̀yin sọ̀rọ̀ ohun ó tọ́ mi bi Jobu ìránṣẹ́ mi ti ṣe. 9 Bẹ́̀ Elifasi, ara Temani, àti Bilidadi, ará Ṣuhi, àti Sofari, ará Naama lọ, wọ́n ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún wọn. Olúwa gbọ́ àdúrà Jobu.

10 Olúwa ìgbèkùn Jobu padà, nígbà ó gbàdúrà fún àwọn ̀rẹ́ rẹ̀; Olúwa bùsi ohun gbogbo ti Jobu ìṣẹ́po méjì ohun ó tẹ́lẹ̀ . 11 Nígbà náà gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀, àti gbogbo àwọn arábìnrin rẹ̀, àti gbogbo àwọn ó ti ṣe ojúlùmọ̀ rẹ̀ ; wọ́n a jẹun nínú ilé rẹ̀. Wọ́n ṣe ìdárò rẹ̀, wọ́n ṣìpẹ̀ fún un nítorí ibi gbogbo Olúwa ti a. Olúkúlùkù ènìyàn pẹ̀fún un ẹyọ owó kọ̀̀kan àti olúkúlùkù ni òrùka wúrà etí kọ̀̀kan.

12 Bẹ́̀ ni Olúwa bùkún ìgbẹ̀yìn Jobu ju ìṣáájú rẹ̀ lọ; ẹgbàá méje (14,000) àgùntàn, ẹgbẹ̀rún mẹ́(6,000) ìbákasẹ, àti ẹgbẹ̀rún (1,000) àjàgà ̀màlúù, àti ẹgbẹ̀rún (1,000) abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. 13 Ó ọmọkùnrin méje àti ọmọbìnrin mẹ́ta. 14 Ó sọ orúkọ àkọ́Jemima, àti orúkọ èkejì ni Kesia àti orúkọ ̀kẹta Kereni-Happuki. 15 Àti gbogbo ilẹ̀ náà, a obìnrin ó ẹwà ọmọ Jobu; baba wọ́n pínlẹ̀ fún wọn nínú àwọn arákùnrin wọn.

16 Lẹ́yìn èyí Jobu ayé ogóje ọdún, ó àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin àti ọmọ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àní ìran mẹ́rin. 17 Bẹ́̀ ni Jobu , ó gbó, ó kún fún ọjọ́ púpọ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-