Publicidade

Jó 5

Ìjìyà jẹ́ èso àìṣòdodo

1 "Ó jẹ́ nísinsin yìí ẹnìkan yóò wa lóhùn?

Tàbí ta ni nínú àwọn ènìyàn mímọ́ ìwọ ó yípadà ?

2 Nítorí ìbínú pa aláìmòye,

ìrunú a pa òpè ènìyàn.

3 Èmi ti aláìmòye ti ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lulẹ̀,

ṣùgbọ́n lójúkan náà mo fi ibùjókòó rẹ̀ .

4 Àwọn ọmọ rẹ̀ jìnnà ewu,

a tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ lójú ibodè,

bẹ́̀ ni aláàbò kan.

5 Ìkórè oko ẹni àwọn ebi ń pa sọ̀ di jíjẹ,

wọ́n wọ inú ̀gún lọ ,

àwọn ìgárá ọlọ́ṣà gbé ohun ìní wọn .

6 ìpọ́njú ti inú erùpẹ̀ jáde ni,

ìyọnu ti ilẹ̀ jáde .

7 Ṣùgbọ́n a ènìyàn sínú wàhálà,

gẹ́gẹ́ ìpẹ́pẹ́ iná ti máa ń ta sókè.

8 "Ṣùgbọ́n ó ṣe tèmi, ̀dọ̀ Ọlọ́run èmi yóò ti ṣìpẹ̀,

ọwọ́ Ọlọ́run èmi yóò máa fi ̀rọ̀ mi .

9 Ẹni ó ṣe ohun ó tóbi a ṣe àwárí,

ohun ìyanu láìní iye.

10 ń rọ̀orí ilẹ̀ ayé

ó ń rán omi sínú ilẹ̀kílẹ̀.

11 Láti gbé àwọn orílẹ̀-èdè lékè

á gbé àwọn ẹni ìbànújẹ́ ga ibi aláìléwu.

12 Ó ìmọ̀ àwọn alárékérekè po,

bẹ́̀ ọwọ́ wọn ìdáwọ́wọn ṣẹ.

13 Ó àwọn ọlọ́gbọ́n nínú àrékérekè ara wọn,

àti ìmọ̀ àwọn òǹrorò ó ṣubú ògèdèǹgbé.

14 Wọ́n sáré wọ inú òkùnkùn ̀sán;

wọ́n fọwọ́ tálẹ̀ ̀sán gangan ẹni òru ni.

15 Ṣùgbọ́n ó gba tálákà ọwọ́ idà,

lọ́wọ́ ẹnu wọn àti lọ́wọ́ àwọn alágbára.

16 Bẹ́̀ ni ìrètí fún tálákà,

àìṣòótọ́ pa ẹnu rẹ̀ mọ́.

17 "Kíyèsi i, ìbùkún ni fún ẹni Ọlọ́run ,

nítorí náà, ṣe gan ìbáwí Olódùmarè.

18 Nítorí òun a máa pa ni lára, síbẹ̀ òun a tún í ìdì ìtura,

ó lọ́gbẹ́, a fi ọwọ́ rẹ̀ di ojú ọgbẹ̀ náà jiná.

19 Yóò gbà ́ nínú ìpọ́njú mẹ́,

àní nínú méje, ibi kan yóò .

20 Nínú ìyanu yóò gbà ́ lọ́wọ́ ikú

àti nínú ogun, yóò gbà ́ lọ́wọ́ idà.

21 A ó pa ́ mọ́ kúrò lọ́wọ́ iná ahọ́n,

bẹ́̀ ìwọ yóò bẹ̀ìparun ó .

22 Ìwọ yóò rẹ́rìn-ín nínú ìparun àti ìyàn,

bẹ́̀ ni ìwọ yóò bẹ̀ẹranko ilẹ̀ ayé.

23 Nítorí ìwọ ti òkúta igbó mulẹ̀,

àwọn ẹranko igbó yóò pẹ̀rẹ àlàáfíà.

24 Ìwọ ó mọ̀ àlàáfíà ni ibùjókòó rẹ ,

ìwọ yóò máa ṣe ìbẹ̀ibùjókòó rẹ, ìwọ yóò ṣìnà.

25 Ìwọ ó mọ̀ pẹ̀irú-ọmọ rẹ ó pọ̀

àti àwọn ọmọ ọmọ rẹ yóò koríko igbó.

26 Ìwọ yóò wọ isà òkú rẹ ògbólógbòó ọjọ́,

síírí ọkà ó gbó á ìgbà ìkórè rẹ̀.

27 "Kíyèsi i, àwa ti wádìí rẹ̀ bẹ́̀ ó !

Gbà á gbọ́, o mọ̀ fún ìre ara rẹ ni."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-