Publicidade

Jó 6

Ìdáhùn Jobu

1 Jobu dáhùn ó si ,

2 "Háà! À wọ́n ìbìnújẹ́ mi nínú òsùwọ̀n,

a le gbé ̀fọ̀ mi orí òsùwọ̀n ṣọ̀kan pọ̀!

3 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ìbá wúwo iyanrìn òkun lọ,

nítorí náà ni ̀rọ̀ mi ṣe ń tàsé.

4 Nítorí ọfà Olódùmarè wọ̀ mi nínú,

oró èyí ọkàn mi ;

ìpayà-ẹ̀Ọlọ́run dúró .

5 Ǹjẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó á máa dún nígbà ó koríko,

tàbí ̀màlúù a máa dún lórí ìjẹ rẹ̀?

6 A ha jẹ ohun adùn àìní iyọ̀,

tàbí adùn ha nínú funfun ẹyin?

7 Ohun ti ̀kan mi kọ̀ láti tọ́,

òun ni ó dàbí oúnjẹ ó mi ṣàárẹ̀.

8 "Háà! èmi ìbá ìbéèrè mi gbà;

àti , Ọlọ́run fi ohun èmi ṣàfẹ́fún mi.

9 Àní Ọlọ́run ìbá jẹ́ pa run,

òun ìbá jẹ́ ṣíwọ́ rẹ̀ ó mi kúrò.

10 Nígbà náà èmi ìbá ìtùnú síbẹ̀,

àní, èmi ìbá ọkàn mi le nínú ìbànújẹ́ mi ti ni :

nítorí èmi fi ̀rọ̀ ẹni mímọ́ ni sin .

11 "agbára mi èmi ó fi retí?

òpin mi èmi ó fi sùúrù?

12 Agbára mi ha ṣe agbára òkúta ?

Ẹran-ara mi í ṣe idẹ?

13 Ìrànlọ́wọ́ mi ha nínú mi:

ọgbọ́n ha ti sálọ kúrò lọ́dọ̀ mi ?

14 "Ẹni àyà rẹ̀ yọ́ dànù, ta ni a máa ṣàánú fún láti ̀dọ̀ ̀rẹ́ rẹ̀ ,

ó ba à kọ ìbẹ̀Olódùmarè sílẹ̀?

15 Àwọn ará mi dàbí odò ṣe gbẹ́kẹ̀

ìṣàn omi odò, wọ́n sàn kọjá lọ.

16 ó dúdú nítorí omi dídì,

àti níbi yìnyín dídì gbé di yíyọ́.

17 Nígbàkígbà wọ́n gbóná wọn a yọ́ sàn lọ,

nígbà oòrùn , wọn a gbẹ kúrò ni ipò wọn.

18 Àwọn oníṣòwò kúrò ̀wọn,

wọ́n gòkè ibi asán, wọ́n run.

19 Ẹgbẹ́ oníṣòwò Tema ń omi,

àwọn oníṣòwò Ṣeba ń dúró wọ́n ìrètí.

20 Wọ́n káàárẹ̀, nítorí wọ́n gbẹ́kẹ̀ wọn e;

wọ́n bẹ̀, wọ́n dààmú.

21 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ̀yin dàbí wọn;

̀yin ìrẹ̀sílẹ̀ mi àyà .

22 Èmi ó ha , ohun fún mi ,

tàbí fún mi ̀bùn nínú ohun ìní yín?

23 Tàbí, gbà lọ́wọ́ ̀ni,

tàbí, padà kúrò lọ́wọ́ alágbára ?

24 "kọ́ mi, èmi ó pa ẹnu mi mọ́

mi wòye níbi mo gbé ti ṣìnà.

25 ó! ̀rọ̀ òtítọ́ ti lágbára

ṣùgbọ́n ni àròyé ìbáwí yín jásí?

26 ̀yin ṣè tún ̀rọ̀ mi ṣe

àti ohùn ẹnu ó dàbí afẹ́fẹ́ ṣe àárẹ̀.

27 Àní ̀yin ṣe gẹ́gẹ́ aláìní baba,

̀yin da iye ̀rẹ́ yín.

28 "Nítorí náà, èyí ó fún yín.

mi! Nítorí ó hàn gbangba ,

ojú yín ni èmi yóò ṣèké.

29 Èmi ń bẹ̀ yín, padà, ó ṣe jásí ̀ṣẹ̀;

àní, tún padà, àre mi ń bẹ nínú ̀rọ̀ yìí.

30 Àìṣedéédéé ha ahọ́n mi?

Ǹjẹ́ ìtọ́ẹnu mi kúkú le mọ ohun ti ó burú ?

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-