Pular para o conteúdo
Publicidade

Levítico 17

̀jẹ̀ jíjẹ jẹ́ èèwọ̀

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ Israẹli: Ohun Olúwa pàṣẹ nìyí, 3 ẹnikẹ́ni nínú ìdílé Israẹli pa màlúù tàbí ̀dọ́-àgùntàn tàbí àgbò nínú ibùdó tàbí ó pa á lẹ́yìn ibùdó 4 un ibi àgọ́ ìpàdé láti fi ẹbọ Olúwa níwájú àgọ́ ìpàdé, ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni ẹni náà lọ́rùn: torí ó ti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀, ẹni náà ni a ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 5 Èyí bẹ́̀ àwọn ọmọ Israẹli le è máa ẹbọ wọn wọn ti ìta gbangba iwájú Olúwa: wọ́n gbọdọ̀ un síwájú àlùfáà àní Olúwa ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé, wọ́n wọn gẹ́gẹ́ ẹbọ àlàáfíà Olúwa. 6 Àlùfáà náà yóò fi ̀jẹ̀ náà wọ́n ibi pẹpẹ Olúwa ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé, yóò sun ̀rẹ̀ òórùn dídùn Olúwa. 7 Nítorí náà, wọn ṣe ẹbọ wọn ère ẹranko mọ́, nínú èyí wọ́n ti ṣe àgbèrè tọ̀ lọ. Èyí yóò jẹ́ ìlànà títí láé láti ìran ìran wọn ń bọ̀.’

8 "ó sọ fún wọn , Ọkùnrin yówù ó jẹ́ ìdílé Israẹli tàbí ti àwọn àlejò ń gbé láàrín wọn ó ẹbọ sísun tàbí ṣe ẹbọ 9 un ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé láti fi ẹbọ Olúwa irú ẹni bẹ́̀ ni a ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.

10 17.10-16: Le 3.17; 7.26,27; 19.26; De 12.16,23-25. " ẹnikẹ́ni jẹ ̀jẹ̀ yálà nínú ìdílé Israẹli tàbí àwọn àlejò ń gbé láàrín wọn, Èmi yóò bínú irú ẹni náà ó jẹ ̀jẹ̀, èmi yóò e kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 11 Nítorí nínú ̀jẹ̀ ni ̀̀, èmi ti fi fún yín lórí pẹpẹ fún ètùtù ọkàn yín: nítorí ̀jẹ̀ ni a fi ń ṣe ètùtù fún ̀ènìyàn. 12 Ìdí nìyí mo fi sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , ̀kankan nínú yín gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀, bẹ́̀ ni àlejò kan ń ṣe àtìpó nínú yín gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀.

13 " Ẹnikẹ́ni yálà nínú àwọn ọmọ Israẹli tàbí àlejò ń gbé láàrín wọn, ó pa ẹranko tàbí ẹyẹ ó yẹ fún jíjẹ gbọdọ̀ ro ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀ ó ó mọ́lẹ̀. 14 Torí ̀gbogbo ̀ni ̀jẹ̀ rẹ̀, torí náà ni mo fi kìlọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli wọn gbọdọ̀ jẹ ̀jẹ̀ ohun abẹ̀kankan, torí nínú ̀jẹ̀ ohun abẹ̀wọ̀nyí ni ̀wọn , ẹnikẹ́ni ó jẹ ́ ni a ó kúrò.

15 " Ẹnikẹ́ni ó jẹ ohun ó sílẹ̀ fúnra rẹ̀, tàbí èyí ẹranko búburú pa kálẹ̀ yálà onílé tàbí àlejò, ó láti fọ aṣọ rẹ̀. ó fi omi wẹ ara rẹ̀, yóò ipò àìmọ́ títí di àṣálẹ́ lẹ́yìn èyí ni yóò di mímọ́. 16 Ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti wẹ ara rẹ̀ fọ aṣọ rẹ̀ náà: ̀bi rẹ̀ yóò lórí ara rẹ̀.’ "

Veja também