Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Crônicas 16

34 16.34: Sm 106.1. Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láé.

35 16.35-36: Sm 106.47,48. lóhùn rara, "Gbà , Ọlọ́run olùgbàlà a wa;

wa jọ o gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè,

àwa ó fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ,

àwa ó yọ̀ nínú ìyìn rẹ̀."

36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,

láé àti láéláé.

Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn ènìyàn , "Àmín," wọ́n "Yin Olúwa."

Veja também