Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 1

Ìdájọ́ Olúwa lórí Ahasiah

1 Lẹ́yìn ikú Ahabu, Moabu ṣọ̀tẹ̀ Israẹli. 2 Nísinsin yìí Ahasiah ti ṣubú láàrín fèrèsé láti òkè yàrá rẹ̀ ó Samaria, ó fi ara pa. Ó rán oníṣẹ́, ó fún wọn , "lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni, bóyá èmi ó ìwòsàn ìfarapa yìí."

3 Ṣùgbọ́n angẹli Olúwa fún Elijah ará Tiṣibi , "Lọ sókè o lọ ìránṣẹ́ ọba Samaria o béèrè lọ́wọ́ wọn, Ṣé nítorí Ọlọ́run Israẹli ni ̀yìn fi jáde lọ ṣèwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu òrìṣà Ekroni?4 Nítorí náà ohun Olúwa sọ èyí, Ìwọ kúrò lórí ibùsùn o dùbúlẹ̀ . Dájúdájú ìwọ yóò !’ " Bẹ́̀ ni Elijah lọ.

5 Nígbà ìránṣẹ́ náà padà ̀dọ̀ ọba, ó béèrè ọwọ́ wọn , "ni ó ̀yin fi tètè padà ?"

6 Wọ́n dáhùn , "Ọkùnrin kan láti pàdé wa, ó fún wa , padà ̀dọ̀ ọba ó rán an yín fún un , "Èyí ni ohun Olúwa : Ṣé nítorí Ọlọ́run Israẹli ni o fi ń rán àwọn ènìyàn láti lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni? Nítorí náà ìwọ fi orí ibùsùn ìwọ dùbúlẹ̀ sílẹ̀. Láìsí àní àní ìwọ yóò kùú!" ’ "

7 Ọba béèrè lọ́wọ́ wọn , "Irú ọkùnrin wo ni ó pàdé yín, ó sọ irú èyí fún un yín?"

8 Wọ́n dáhùn , "Ó jẹ́ ọkùnrin ó wọ ̀onírun lára pẹ̀̀àmùrè aláwọ ó gbà yíká ìbàdí rẹ̀."

Ọba , "Elijah ará Tiṣibi ni."

9 Ó rán balógun pẹ̀àwọn ẹgbẹ́ ogun àádọ́ta rẹ̀. Balógun náà gòkè tọ Elijah lọ, ẹni ó jókòó orí òkè, wọ́n fún un , "Ènìyàn Ọlọ́run, ọba , Sọ̀kalẹ̀ !’ "

10 Elijah balógun lóhùn , "ó jẹ́ ènìyàn Ọlọ́run ni , iná ó sọ̀kalẹ̀ láti òkè ̀run ó ìwọ àti àwọn àádọ́ta ọkùnrin rẹ!" Nígbà náà iná náà sọ̀kalẹ̀ láti òkè ̀run ó balógun àti àwọn ènìyàn rẹ̀.

11 Ọba tún rán balógun àádọ́ta pẹ̀àwọn ènìyàn àádọ́ta rẹ̀ Elijah. Balógun náà fún un , "Ènìyàn Ọlọ́run, èyí ni ohun ọba sọ, Sọ̀kalẹ̀ kánkán!’ "

12 "èmi jẹ́ ènìyàn Ọlọ́run," Elijah dáhùn, "Ǹjẹ́ iná ó sọ̀kalẹ̀ láti ̀run ó run àti àwọn àádọ́ta ènìyàn rẹ!" Nígbà náà iná Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀ láti ̀run ó o run pẹ̀àwọn àádọ́ta ènìyàn rẹ̀.

13 Bẹ́̀ ni ọba tún rán balógun kẹta pẹ̀àwọn àádọ́ta ọkùnrin. Balógun ̀̀kẹ́ta lọ òkè, ó kúnlẹ̀ lórí orókún rẹ̀ níwájú Elijah. "Ènìyàn Ọlọ́run," Ó bẹ̀bẹ̀ , "Ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, jọ̀wọ́ jẹ́ ̀mi àti ̀àwọn àádọ́ta ìránṣẹ́ rẹ wọ̀nyí ṣọ̀wọ́n ojú rẹ! 14 ó, iná ti sọ̀kalẹ̀ láti ̀run láti àwọn balógun méjì àràádọ́ta àkọ́kọ́ pẹ̀àràádọ́ta wọn. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ojúrere fún ̀mi!"

15 Angẹli Olúwa sọ fún Elijah , "Sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀rẹ̀; ṣe bẹ̀rẹ̀." Bẹ́̀ ni Elijah dìde ó sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀rẹ̀ ̀dọ̀ ọba.

16 Ó sọ fún ọba , "Èyí ni ohun Olúwa , Ṣé nítorí Ọlọ́run Israẹli fún láti ni ìwọ fi rán ìránṣẹ́ lọ ̀dọ̀ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni láti lọ ṣe ìwádìí?Nítorí o ṣe èyí, ìwọ dìde lórí ibùsùn o dùbúlẹ̀ láìsí àní àní ìwọ yóò !" 17 Bẹ́̀ ó , gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa Elijah ti sọ.

Nítorí Ahasiah ọmọ, Jehoramu jẹ ọba ọdún kejì Jehoramu ọmọ Jehoṣafati ọba Juda. 18 Àti ti gbogbo àwọn ohun ó ṣẹlẹ̀ nígbà ìjọba Ahasiah, àti ohun ó ṣe, ṣe a ha kọ wọ́n inú ìwé ọdọọdún ti àwọn ọba Israẹli?

Veja também