Publicidade

2 Reis 11

Ataliah àti Joaṣi

1 11.1-20: 2Ki 22.10–23.21. Nígbà Ataliah ìyá Ahasiah i ọmọ rẹ̀ ti , ó tẹ̀síwájú láti pa gbogbo ìdílé ọba náà run. 2 Ṣùgbọ́n Jehoṣeba ọmọbìnrin ọba Jehoramu àti arábìnrin Ahasiah, Joaṣi ọmọ Ahasiah, ó i lọ kúrò láàrín àwọn ọmọ-aládébìnrin ti ọba náà, ó díẹ̀ a pa. Ó gbé òhun àti olùtọ́rẹ̀ sínú ìyẹ̀láti fi pamọ́ kúrò fún Ataliah; bẹ́̀ ni a pa á. 3 Ó ìpamọ́ pẹ̀olùtọ́ilé a kọ́ fún Olúwa fún ọdún mẹ́nígbà Ataliah fi jẹ ọba lórí ilẹ̀ náà.

4 ọdún keje, Jehoiada ránṣẹ́ ó àwọn olórí lórí ̀rọ̀̀rún, pẹ̀àwọn balógun àti àwọn olùṣọ́, ó wọn ̀dọ̀ rẹ̀ nínú ilé a kọ́ fún Olúwa. Ó ṣe májẹ̀pẹ̀wọn, ó fi wọ́n abẹ́ ìbúra nínú ilé a kọ́ fún Olúwa. Níbẹ̀ ni ó fi ọmọkùnrin ọba hàn wọ́n. 5 Ó pàṣẹ fún wọn, , "Ìwọ ó nínú àwọn ẹgbẹ́ mẹ́tẹ̀̀ta ó ń lọ fún iṣẹ́ ìsìn ọjọ́ ìsinmiìdámẹ́ta yín fún ṣíṣọ́ ààfin ọba. 6 Ìdámẹ́ta ẹnu ìlẹ̀kùn huri, àti ìdámẹ́ta ẹnu ìlẹ̀kùn ̀yìn olùṣọ́, ó yípadà ṣíṣọ́ ilé a kọ́, 7 àti ̀yin ó ẹgbẹ́ kejì yòókù í lọ ibi iṣẹ́ ìsìn ọjọ́ ìsinmi gbogbo ni ó ṣọ́ ilé a kọ́ fún Olúwa fún ọba. 8 ibùjókòó yín ọba , olúkúlùkù ọkùnrin pẹ̀ohun ìjà rẹ̀ ọwọ́ rẹ̀. Ẹnikẹ́ni ó súnmọ́ ọgbà yìí gbọdọ̀ . dúró súnmọ́ ọba ibikíbi ó lọ."

9 Olórí àwọn ̀rọ̀̀rún ṣe gẹ́gẹ́ Jehoiada àlùfáà ti pa á láṣẹ. Olúkúlùkù àwọn ọkùnrin rẹ̀ àwọn ó ń lọ iṣẹ́ ìsìn ọjọ́ ìsinmi àti àwọn wọ́n ̀dọ̀ Jehoiada àlùfáà. 10 Nígbà náà, ó fún àwọn olórí àwọn ̀kọ̀ àti àwọn àpáta ó ti jẹ́ ti ọba Dafidi ó nínú ilé a kọ́ fún Olúwa. 11 Àwọn olùṣọ́, olúkúlùkù pẹ̀ohun ìjà rẹ̀ ọwọ́ rẹ̀, wọ́n dúró ṣinṣin yìí ọba lẹ́bàá pẹpẹ àti ilé ìhà gúúsù ìhà àríwá ilé a kọ́ fun Olúwa náà.

12 Jehoiada ọmọkùnrin ọba jáde, ó gbé adé náà e: ó fún un ̀májẹ̀, wọ́n kéde ọba rẹ̀. Wọ́n fi àmì òróró yàn án, àwọn ènìyàn pa àtẹ́wọ́, wọ́n kígbe, "̀ọba ó gùn."

13 Nígbà Ataliah gbọ́ ariwo àwọn olùṣọ́ àti àwọn ènìyàn ń pa, ó lọ ̀dọ̀ àwọn ènìyàn nínú ilé a kọ́ fún Olúwa. 14 Ó ó, níbẹ̀ ni ọba, ó dúró lẹ́bàá òpó, gẹ́gẹ́ àṣà ti . Àwọn balógun àti àwọn afùnpè ̀ọba, gbogbo àwọn ènìyàn ilé náà ń yọ̀, wọ́n ń fun ìpè pẹ̀. Nígbà náà Ataliah fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya. Ó kégbe , "̀tẹ̀! ̀tẹ̀!"

15 Jehoiada àlùfáà pàṣẹ fún olórí ̀rọ̀̀rún, ta ni ó ìkáwọ́ ̀wọ́ ogun: "u jáde láàrín àwọn ẹgbẹ́ ogun yìí o fi ipa idà ẹnikẹ́ni ó tẹ̀." Nítorí àlùfáà ti sọ, "A gbọdọ̀ pa á nínú ilé a kọ́ fún Olúwa." 16 Bẹ́̀ ni wọ́n fi agbára un ó ti ibi àwọn ẹṣin ń wọ ilẹ̀ ààfin ọba àti níbẹ̀ ni a ti pa á.

17 Nígbà náà ni Jehoiada májẹ̀láàrín Olúwa àti ọba àti àwọn ènìyàn yóò jẹ́ ènìyàn Olúwa. Ó májẹ̀láàrín ọba àti àwọn ènìyàn pẹ̀. 18 Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà lọ ilé a kọ́ fún òrìṣà Baali wọ́n ya á bolẹ̀. Wọ́n fọ́ àwọn pẹpẹ àti òrìṣà wẹ́wẹ́. Wọ́n pa Mattani àlùfáà Baali níwájú àwọn pẹpẹ.

Nígbà náà, Jehoiada àlùfáà náà yan àwọn olùṣọ́ ilé a kọ́ fún Olúwa. 19 Ó pẹ̀u rẹ̀ àwọn olórí ̀rọ̀̀rún àti gbogbo balógun àti àwọn olùṣọ́ àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà àti lápapọ̀, wọ́n ọba sọ̀kalẹ̀ láti ilé a kọ́ fún Olúwa. Wọ́n wọ inú ààfin lọ, wọ́n wọlé nípa ìlẹ̀kùn ti àwọn olùṣọ́. Ọba ààyè rẹ̀ orí ìtẹ́ ọba. 20 Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yọ̀, ìlú náà dákẹ́ jẹ́́. Nítorí a pa Ataliah pẹ̀idà náà ààfin ọba.

21 Joaṣi jẹ́ ọmọ ọdún méje nígbà ó bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-