Publicidade

2 Reis 3

̀tẹ̀ Moabu

1 Jehoramu ọmọ Ahabu di ọba Israẹli Samaria ọdún kejìdínlógún ti Jehoṣafati ọba Juda, ó jẹ ọba fún ọdún méjìlá. 2 Ó ṣe búburú níwájú Olúwa, ṣùgbọ́n í ṣe ti ìyá àti baba rẹ̀ ti ṣe. Ó gbé òkúta ère ti Baali baba rẹ̀ ti ṣe kúrò. 3 ó tilẹ̀ jẹ́ ó fi ara mọ́ ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, ó ti fi Israẹli láti dẹ́ṣẹ̀; kúrò lọ́dọ̀ wọn.

4 Nísinsin yìí Meṣa ọba Moabu ń sin àgùntàn, ó gbọdọ̀ fi fún ọba Israẹli pẹ̀̀kẹ́ márùn-ún ̀dọ́-àgùntàn àti pẹ̀irun ̀kẹ́ márùn-ún (100,000) àgbò. 5 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ikú Ahabu, ọba Moabu ṣọ̀tẹ̀ lórí ọba Israẹli. 6 Lásìkò ìgbà yìí ọba Jehoramu jáde kúrò Samaria ó gbogbo Israẹli ipò padà. 7 Ó ránṣẹ́ yìí Jehoṣafati ọba Juda , "Ọba Moabu ṣọ̀tẹ̀ mi. Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀mi láti lọ Moabu ?"

Ọba Juda dáhùn , "Èmi yóò lọ pẹ̀rẹ. Èmi jẹ́ gẹ́gẹ́ ìwọ ti , ènìyàn rẹ ènìyàn mi, ẹṣin mi ẹṣin rẹ."

8 "Nípa ̀wo ni àwa yóò gbà dojúkọ wọ́n?" Ó béèrè.

"Lọ́aginjù Edomu," ó dáhùn.

9 Bẹ́̀ ni ọba Israẹli jáde lọ pẹ̀ọba Juda àti ọba Edomu. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n yíká fún ọjọ́ méje. Àwọn ọmọ-ogun wọn omi púpọ̀ fún ara wọn tàbí fún ẹranko ó pẹ̀wọn.

10 "ni?" ọba Israẹli kígbe sókè. "Ṣé Olúwa pe àwa ọba mẹ́tẹ̀̀ta papọ̀ láti fi Moabu lọ́wọ́?"

11 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati , "Ṣé wòlíì Olúwa níbí, àwa ìbá ti ̀dọ̀ rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?"

̀kan lára àwọn ìránṣẹ́ ọba Israẹli dáhùn , "Eliṣa ọmọ Ṣafati níbí. Ó máa sábà bu omi ọwọ́ Elijah."

12 Jehoṣafati , "̀rọ̀ Olúwa pẹ̀rẹ̀." Bẹ́̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati àti ọba Edomu sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ́ lọ.

13 Eliṣa fún ọba Israẹli , "ni àwa ṣe pẹ̀ara wa? Lọ sọ́dọ̀ wòlíì baba rẹ àti wòlíì ti ìyá rẹ."

Ọba Israẹli a lóhùn, "Rárá, nítorí Olúwa ni ó pe àwa ọba mẹ́tẹ̀̀ta papọ̀ láti fi Moabu lọ́wọ́."

14 Eliṣa , "Gẹ́gẹ́ ó ti Olúwa àwọn ọmọ-ogun láyé, ẹni mo ń sìn èmi ̀wọ̀ fún ojú Jehoṣafati ọba Juda, èmi ó tàbí èmi ti . 15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, fún mi ohun èlò orin olókùn."

Nígbà akọrin náà n kọrin, ọwọ́ Olúwa sórí Eliṣa. 16 Ó , "Èyí ni ohun Olúwa sọ, Jẹ́ àfonífojì kún fún ̀gbun.17 Nítorí èyí ni Olúwa , o í afẹ́fẹ́ tàbí òjò, bẹ́̀ ni àfonífojì yìí yóò kún pẹ̀omi, àti ìwọ àti ẹran ̀sìn àti pẹ̀àwọn ẹran yóò mu. 18 Èyí jẹ́ ohun lágbára níwájú Olúwa, yóò fi Moabu e yín lọ́wọ́ pẹ̀. 19 Ìwọ yóò bi gbogbo ìlú olódi àti gbogbo àgbà ìlú ṣubú. Ìwọ yóò gbogbo igi dáradára ṣubú, gbogbo orísun omi dúró, o pa gbogbo pápá dáradára pẹ̀òkúta run."

20 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, àsìkò ẹbọ, níbẹ̀ ni omí sàn láti ̀kánkán Edomu! Ilé náà kún pẹ̀omi.

21 Nísinsin yìí gbogbo ará Moabu gbọ́ àwọn ọba láti wọn . Bẹ́̀ ni gbogbo ènìyàn, ọmọdé àti àgbà ó ja ogun wọn wọ́n sókè wọ́n dúró etí ilẹ̀. 22 Nígbà wọ́n dìde òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, oòrùn ti tàn orí omi náà àwọn ará Moabu ìkọjá ̀, omi náà pupa ̀jẹ̀. 23 "̀jẹ̀ ni èyí!" wọ́n , "Àwọn ọba wọ̀nyí ti wọn pa ara wọn ìpakúpa. Nísinsin yìí àwọn ìkógun Moabu!"

24 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn ará Moabu ibùdó ti Israẹli, àwọn ará Israẹli dìde, wọ́n kọlù wọ́n títí wọ́n fi sálọ. Àwọn ará Israẹli gbógun ilẹ̀ náà wọ́n pa Moabu run. 25 Wọ́n wọ gbogbo ìlú náà olúkúlùkù ènìyàn, wọ́n ju òkúta gbogbo ohun dáradára orí pápá títí ó fi run. Wọ́n gbogbo orísun omi dúró wọ́n gbogbo orísun dáradára. Kiri-Hareseti nìkan ni wọ́n fi òkúta rẹ̀ sílẹ̀ ààyè rẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ológun pẹ̀kànnàkànnà yíká, wọ́n kọlù ìlú náà.

26 Nígbà ọba Moabu i ogun náà le ju ti òun lọ, ó idà pẹ̀̀́dẹ́gbẹ̀rin (700) ọkùnrin onídà láti pẹ̀ọba Edomu, ṣùgbọ́n wọn yege. 27 Nígbà náà ó àkọ́ọmọkùnrin rẹ̀, jẹ́ gẹ́gẹ́ ọba, ó fi ẹbọ sísun orí ògiri ìlú. Wọ́n bínú lórí Israẹli púpọ̀púpọ̀; wọ́n yọ́ kúrò wọ́n padà ìlú wọn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-