Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Reis 5

Ìwòsàn Naamani adẹ́tẹ̀

1 Naamani jẹ́ olórí ogun ọba Aramu. Ó jẹ́ ènìyàn ńlá níwájú ̀rẹ̀, wọ́n bu ọlá fún un, nítorí nípasẹ̀ rẹ̀ ni Olúwa ti fi ìṣẹ́gun fún Aramu. Òun jẹ́ alágbára, akọni ọkùnrin ṣùgbọ́n, ó dẹ́tẹ̀.

2 Nísinsin yìí ẹgbẹgbẹ́ láti Aramu ti jáde lọ láti ọmọ obìnrin kékeré kan ìgbèkùn láti Israẹli, ó sin ìyàwó Naamani. 3 Ó sọ fún ̀rẹ̀ obìnrin , "ó jẹ́ ̀mi wòlíì ó Samaria! Yóò ó sàn kúrò nínú ̀tẹ̀ rẹ̀."

4 Naamani lọ ̀dọ̀ ̀rẹ̀ ó fún un ohun ọmọbìnrin Israẹli ti sọ. 5 "gbogbo ̀, lọ," ọba Aramu a lóhùn , "Èmi yóò fi ìwé ránṣẹ́ ọba Israẹli." Bẹ́̀ ni Naamani lọ, ó pẹ̀rẹ̀ tálẹ́ǹtì fàdákà mẹ́wàá, ẹgbẹ̀rún mẹ́(6,000) ìwọ̀n wúrà àti ìpààrọ̀ aṣọ mẹ́wàá. 6 Ìwé ó lọ sọ́dọ̀ ọba Israẹli , "Pẹ̀ìwé yìí èmi ń rán ìránṣẹ́ mi Naamani o ó sàn kúrò nínú ̀tẹ̀ rẹ̀."

7 ọba Israẹli ti ka ìwé náà ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó , "Èmi ha jẹ́ Ọlọ́run? Ǹjẹ́ èmi le pa n ààyè padà? ni ó eléyìí rán ènìyàn mi láti wo ààrùn ̀tẹ̀ rẹ sàn, wo ó ti ń ̀láti ìjà pẹ̀mi!"

8 Nígbà Eliṣa ènìyàn Ọlọ́run gbọ́ ọba Israẹli ti ya aṣọ rẹ̀, ó rán iṣẹ́ yìí i , "ni ó o fi fa aṣọ rẹ ya? Jẹ́ ọkùnrin náà ̀dọ̀ mi. Òun yóò mọ̀ wòlíì Israẹli." 9 Bẹ́̀ ni Naamani lọ pẹ̀ẹṣin rẹ̀ àti kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó dúró ẹnu-ọ̀ilé Eliṣa. 10 Eliṣa rán ìránṣẹ́ láti lọ sọ fún un , "Lọ, wẹ̀ ara rẹ ìgbà méje odò Jordani, ẹran-ara rẹ yóò tún padà bọ̀ sípò, ìwọ yóò mọ́."

11 Ṣùgbọ́n Naamani lọ pẹ̀ìbínú ó , "Mo lérò yóò dìde jáde nítòótọ́ mi, yóò pe orúkọ Olúwa Ọlọ́run, fi ọwọ́ rẹ̀ lórí ibẹ̀ ó wo ̀tẹ̀ mi sàn. 12 Abana àti Fapari, odò Damasku ha dára ju gbogbo omi Israẹli lọ? Ṣé èmi le wẹ̀ nínú wọn n mọ́?" Bẹ́̀ ni ó yípadà, ó lọ pẹ̀ìrunú.

13 Ìránṣẹ́ Naamani lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ó , "Baba mi, wòlíì ti sọ fún láti ṣe ohun ńlá kan, ṣé ìwọ ti ṣe, mélòó mélòó nígbà náà, nígbà ó sọ fún , Wẹ̀ o mọ́’!" 14 Bẹ́̀ ni ó sọ̀kalẹ̀ lọ ó tẹ ara rẹ̀ bọ inú odò Jordani ìgbà méje, gẹ́gẹ́ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ fún un, ẹran-ara rẹ̀ tún padà mímọ́ gẹ́gẹ́ ọmọkùnrin kékeré.

Veja também