Publicidade

2 Samuel 6

12 6.12-19: 1Ki 15.1–16.3. A fún Dafidi ọba , "Olúwa ti bùkún fún ilé Obedi-Edomu, àti gbogbo èyí í ṣe tirẹ̀, nítorí àpótí ̀Ọlọ́run." Dafidi lọ, ó àpótí ̀náà gòkè láti ilé Obedi-Edomu ìlú Dafidi pẹ̀ayọ̀. 13 Ó ṣe nígbà àwọn ènìyàn ó ru àpótí ̀Olúwa ṣí ẹsẹ̀ mẹ́, òun a fi màlúù àti ẹran àbọ́pa ẹbọ. 14 Dafidi fi gbogbo agbára rẹ̀ níwájú Olúwa; Dafidi wọ efodu ̀gbọ̀. 15 Bẹ́̀ ni Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli gbé àpótí ̀Olúwa gòkè , pẹ̀ìhó ayọ̀, àti pẹ̀ìró ìpè.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-