Pular para o conteúdo
Publicidade

Êxodo 10

Ìyọnu Eṣú

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Lọ ̀dọ̀ Farao, mo ti ṣé àyà Farao le àti àyà àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, èmi o ba le ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu mi láàrín wọn. 2 ̀yin ki ó le sọ fún àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ ọmọ yín; mo ti jẹ àwọn ará Ejibiti àti mo ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu láàrín wọn. ìwọ ba á le mọ̀ Èmi ni Olúwa."

3 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, tiwọn fún un , "Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run àwọn Heberu sọ, Yóò ti pẹ́ to ti ìwọ yóò kọ̀ láti tẹrí ara rẹ ba iwájú mi? Jẹ́ àwọn ènìyàn mi ó lọ, wọn ó sìn mi. 4 ìwọ kọ̀ láti jẹ́ wọn lọ, èmi yóò eṣú wa orílẹ̀-èdè rẹ ̀la. 5 Wọn yóò bo gbogbo ilẹ̀. Wọn yóò ba ohun gbogbo ó fún lẹ́yìn òjò yìnyín jẹ́, ó fi dórí gbogbo igi ó ń dàgbà ni ilẹ̀ rẹ. 6 Wọn yóò kún gbogbo ilé rẹ àti ilé àwọn ìjòyè rẹ àti ilé gbogbo àwọn ará Ejibiti. Ohun ti baba rẹ tàbí baba baba rẹ ì láti ìgbà wọ́n ti ilẹ̀ náà títí di àkókò yìí.’ " Nígbà náà ni Mose pẹ̀yìndà kúrò níwájú Farao.

7 Àwọn ìjòyè Farao sọ fún un, "Yóò ti pẹ́ to ọkùnrin yìí yóò máa jẹ́ ìkẹ́kùn fún wa? Jẹ́ àwọn ènìyàn yìí lọ, wọn ó le sìn Olúwa Ọlọ́run wọn. Ṣe ìwọ ṣe àkíyèsí síbẹ̀ , ilẹ̀ Ejibiti ti parun tán?"

8 Nígbà náà ni a Aaroni àti Mose padà iwájú Farao ó fún wọn , "lọ sìn Olúwa Ọlọ́run yín. Ṣùgbọ́n àwọn ta ni nínú yín ni yóò ha lọ."

9 Mose dáhùn ó , "A ó lọ pẹ̀àwọn ọmọdé àti àgbà wa, pẹ̀àwọn ọmọ wa ọkùnrin àti ọmọ wa obìnrin pẹ̀agbo àgùntàn wa àti agbo màlúù wa nítorí a gbọdọ̀ ṣe àjọ fún Olúwa."

10 Farao , "Mo fi Olúwa búra èmi yóò jẹ́ lọ, pẹ̀àwọn obìnrin yín àti àwọn ọmọ wẹ́wẹ́, dájúdájú èrò ibi ń bẹ nínú yín. 11 Rárá! Ọkùnrin yín nìkan ni ó lọ, láti lọ sin Olúwa, níwọ̀n ìgbà ó jẹ́ èyí ni ̀yin ń béèrè fún." Wọ́n Mose àti Aaroni kúrò iwájú Farao.

12 ìgbà náà ni Olúwa sọ fún Mose, "Gbé ọwọ́ rẹ sókè lórí Ejibiti ̀pọ̀lọpọ̀ eṣú bo gbogbo ilẹ̀, ó ba gbogbo ohun ̀gbìn ó ni inú oko wọn jẹ́, àní gbogbo ohun òjò yìnyín bàjẹ́ tan."

13 Nígbà náà ni Mose na ̀ọwọ́ rẹ̀ sórí ilẹ̀ Ejibiti, Olúwa afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn fẹ́ kọjá lórí ilẹ̀ náà ni gbogbo ̀sán àti ni gbogbo òru ni ọjọ́ náà. òwúrọ̀ afẹ́fẹ́ náà ti gbá ̀pọ̀lọpọ̀ eṣú ; 14 10.14,15: If 9.2,3.wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, wọ́n ibi gbogbo orí ilẹ̀ àìmoye, ṣáájú àkókò yìí irú ìyọnu eṣú bẹ́̀ , irú rẹ mọ́ lẹ́yìn èyí. 15 Wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ ilẹ̀ fi di dúdú. Wọ́n ba gbogbo ohun tókù orí ilẹ̀ lẹ́yìn òjò yìnyín jẹ́; gbogbo ohun ̀gbìn ó inú oko àti gbogbo èso ó lórí igi. ewé ó lórí igi tàbí lórí ohun ̀gbìn gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.

16 Farao yára ránṣẹ́ pe Mose àti Aaroni, ó sọ fún wọn , "Èmi ti ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín àti i yín pẹ̀. 17 Nísinsin yìí dáríjì mi lẹ́̀kan i gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run yín ó ìpọ́njú yìí kúrò ̀dọ̀ mi."

18 Nígbà náà ni Mose kúrò iwájú Farao ó gbàdúrà Olúwa. 19 Olúwa afẹ́fẹ́ náà padà di afẹ́fẹ́ líle láti apá ìwọ̀-oòrùn láti gbá àwọn eṣú náà kúrò orí ilẹ̀ Ejibiti lọ sínú Òkun Pupa. Bẹ́̀ ni ẹyọ eṣú kan ṣẹ́orí ilẹ̀ Ejibiti. 20 Síbẹ̀ Olúwa ṣe àyà Farao le, jẹ́ àwọn ọmọ Israẹli lọ.

Òkùnkùn bo ilẹ̀

21 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Gbé ọwọ́ rẹ sókè ojú ̀run òkùnkùn à le bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti; àní òkùnkùn biribiri." 22 10.22: Sm 105.28; If 16.10.Nígbà náà ni Mose gbé ọwọ́ rẹ sókè ojú ̀run, òkùnkùn biribiri bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti fún ọjọ́ mẹ́ta. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli ìmọ́lẹ̀ ibi wọn ń gbé. 23 ẹni ó le è ríran ẹlòmíràn tàbí ó kúrò ibi ó fún ọjọ́ mẹ́ta. Síbẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli ni ìmọ́lẹ̀ ni gbogbo ibi wọ́n ń gbé.

24 Farao ránṣẹ́ pe Mose ó fún un , "Lọ sin Olúwa, kódà àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé lọ pẹ̀yín, ṣùgbọ́n ìwọ ó fi agbo àgùntàn àti agbo màlúù yín sílẹ̀."

25 Ṣùgbọ́n Mose sọ , "Ìwọ gbọdọ̀ fún wa láààyè láti ẹbọ àti ọrẹ ẹbọ sísun iwájú Olúwa Ọlọ́run wa. 26 Àwọn ohun ̀sìn wa gbọdọ̀ lọ pẹ̀wa, a yóò fi pátákò ẹsẹ̀ ẹran sílẹ̀. A láti lára wọn fún sínsin Olúwa Ọlọ́run wa, ìgbà a ibẹ̀ ni a ó to mọ̀ ohun ti a ó láti fi sin Olúwa."

27 Ṣùgbọ́n Olúwa ọkàn Farao le, ṣetán láti jẹ́ wọn lọ. 28 Farao sọ fún Mose , "Kúrò iwájú mi! i dájú o iwájú mi mọ́! Ọjọ́ ìwọ ojú mi ni ìwọ yóò kùú."

29 Mose dáhùn , gẹ́gẹ́ ìwọ ti , "Èmi yóò iwájú rẹ mọ́."

Veja também