Pular para o conteúdo
Publicidade

Jó 11

Sofari fi ̀sùn irọ́ pípa àti àìṣòótọ́ kan Jobu

1 Ìgbà náà ni Sofari, ará Naama, dáhùn, ó ,

2 "A ha ṣe a máa dáhùn ̀pọ̀lọpọ̀ ̀rọ̀?

A ha fi gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí da ènìyàn láre?

3 Ṣé àmọ̀tán rẹ le ènìyàn pa ẹnu wọn mọ́ ?

Ṣé ẹnikẹ́ni ìwọ yọ ṣùtì ni?

4 Ìwọ à ti fún Ọlọ́run , Ìṣe mi jẹ́ aláìléérí,

èmi mọ́ ojú rẹ.

5 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ìbá jẹ́ sọ̀rọ̀,

ó ya ẹnu rẹ̀

6 ó fi àṣírí ọgbọ́n hàn ́ , ó pọ̀ ju òye ènìyàn lọ,

nítorí náà, mọ̀ Ọlọ́run ti

gbàgbé àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ kan.

7 "Ìwọ ha le ṣe àwárí ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run ?

Ìwọ ha le ṣe àwárí ibi Olódùmarè bi?

8 Ó ga ju àwọn ̀run lọ; ni ìwọ le è ṣe?

Ó jìn ju jíjìn isà òkú lọ; ni ìwọ le mọ̀?

9 Ìwọ̀n rẹ̀ gùn ju ayé lọ,

ó ibú ju òkun lọ.

10 "òun rékọjá, ó ọnà

tàbí ó ni ìdájọ́, ǹjẹ́, ta ni ó i lọ́wọ́?

11 Òun à mọ ẹlẹ́tàn ènìyàn;

àti ṣé òun ohun búburú, ṣé òun i fi iyè i?

12 Ṣùgbọ́n òmùgọ̀ ènìyàn ki yóò di ọlọ́gbọ́n

bi ko ti rọrùn fún ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó láti ènìyàn.

13 "ìwọ fi ọkàn rẹ fún un,

ìwọ na ọwọ́ rẹ ̀dọ̀ rẹ̀,

14 ìwọ gbé ̀ṣẹ̀ ń bẹ ọwọ́ rẹ sọnù

ìwọ jẹ́ aburú gbé nínú àgọ́ rẹ,

15 nígbà náà ni ìwọ ó gbé ojú rẹ sókè láìní àbàwọ́n,

àní ìwọ yóò dúró ṣinṣin, ìwọ yóò bẹ̀.

16 Nítorí ìwọ ó gbàgbé ìṣòro rẹ;

ìwọ ó rántí rẹ̀ omi ó ti sàn kọjá lọ.

17 Ọjọ́ ayé rẹ yóò mọ́lẹ̀ ju ̀sán gangan lọ,

òkùnkùn tilẹ̀ ́ mọ́lẹ̀ nísinsin yìí, ìwọ ó dàbí òwúrọ̀.

18 Ìwọ ó láìléwu, nítorí ìrètí ;

àní ìwọ ó rin ilé rẹ , ìwọ ó sinmi àlàáfíà.

19 Ìwọ ó dùbúlẹ̀ pẹ̀, yóò ẹni yóò dẹ́rùbà ́,

àní ènìyàn yóò máa ojúrere rẹ.

20 Ṣùgbọ́n ojú ìkà ènìyàn yóò mófo;

gbogbo ̀àbáyọ ni yóò wọ́n,

ìrètí wọn a dàbí ẹni ó jọ̀wọ́ ̀rẹ̀ lọ́wọ́."

Veja também