Publicidade

Jó 4

̀rọ̀ Elifasi: Ọlọ́run í fi ìyà jẹ olódodo

1 Ìgbà náà ni Elifasi, ará Temani dáhùn ,

2 "àwa fi ẹnu e, láti sọ̀rọ̀, ìwọ o ha banújẹ́?

Ṣùgbọ́n ta ni ó pa ̀rọ̀ mọ́ ẹnu láìsọ?

3 Kíyèsi i, ìwọ ti kọ́ ̀pọ̀ ènìyàn,

ìwọ ṣá ti ọwọ́ aláìlera le.

4 ̀rọ̀ rẹ ti gbé àwọn ń ṣubú lọ dúró,

ìwọ ti eékún àwọn ń wárìrì lera.

5 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ó , ó rẹ̀ ́, ó kọlù ́;

ara rẹ lélẹ̀.

6 Ìbẹ̀Ọlọ́run rẹ ha jẹ́ ìgbẹ́kẹ̀rẹ

àti ìdúró ̀rẹ ha jẹ́ ìrètí rẹ?

7 "Èmi bẹ̀ ́ rántí, ta ni ó ṣègbé láìṣẹ̀?

Tàbí níbo ni a gbé olódodo kúrò ?

8 Àní èmi ti i , àwọn ń ṣe ìtulẹ̀ ̀ṣẹ̀,

wọ́n fún irúgbìn ìwà búburú, wọn a èso rẹ̀ náà.

9 Nípa ìfẹ́ Ọlọ́run wọn a ṣègbé,

nípa èémí ìbínú rẹ̀ wọn a parun.

10 Bíbú ramúramù kìnnìún àti ohùn òǹrorò kìnnìún

àti eyín àwọn ẹgbọrọ kìnnìún a .

11 Kìnnìún kígbe, nítorí àìrí ohun ọdẹ,

àwọn ẹgbọrọ kìnnìún sísanra ni a túká kiri.

12 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí a fi ohun àṣírí kan hàn fún mi,

etí mi gbà díẹ̀ nínú rẹ̀.

13 ìrò inú lójú ìran òru,

nígbà oorun èjìká kùn ènìyàn.

14 ̀àti ìwárìrì

ó gbogbo egungun mi pépé.

15 Nígbà náà ni ̀kan kọjá lọ iwájú mi,

irun ara mi dìde dúró ṣánṣán.

16 Ó dúró jẹ́́,

ṣùgbọ́n èmi le wo àpẹẹrẹ ìrí rẹ̀,

àwòrán kan hàn níwájú mi,

ìdákẹ́rọ́rọ́ , mo gbóhùn kan ,

17 Ẹni kíkú le jẹ́ olódodo ju Ọlọ́run,

ènìyàn ha le mọ́ ju ẹlẹ́dàá rẹ̀ ?

18 Kíyèsi i, òun gbẹ́kẹ̀àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀,

nínú àwọn angẹli rẹ̀ ó ̀ṣẹ̀.

19 Mélòó mélòó àwọn ń gbé inú ilé amọ̀,

ẹni ìpìlẹ̀ wọ́n jásí erùpẹ̀

yóò di rírun kòkòrò.

20 A pa wọ́n run láàrín òwúrọ̀ àti àṣálẹ́

wọ́n parun títí láé, láìrí ẹni á .

21 A ha okùn iye wọ́n kúrò ?

Wọ́n , àní láìlọ́gbọ́n?

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-