Publicidade

Jó 7

Jobu ha ni ìrètí ?

1 "Ṣé ìjà ha si fún ènìyàn lórí ilẹ̀?

Ọjọ́ rẹ̀ pẹ̀ha dàbí ọjọ́ alágbàṣe?

2 ọmọ ̀dọ̀ máa ń kánjú bojú wo òjìji,

àti alágbàṣe ti í kánjú wo ̀owó iṣẹ́ rẹ̀.

3 Bẹ́̀ ni a mi ìbànújẹ́ ̀pọ̀lọpọ̀ oṣù,

òru ìdáni-lágara ni a sílẹ̀ fún mi.

4 Nígbà ti mo dùbúlẹ̀, èmi , Nígbà wo ni èmi ó dìde?

òru yóò kọjá, ó fún mi láti síyìn-ín sọ́hùn-ún, títí yóò fi di àfẹ̀mọ́júmọ́.

5 Kòkòrò àti ògúlùtu erùpẹ̀ ni á fi wọ̀ mi ni aṣọ,

awọ ara mi , o di bíbàjẹ́.

6 "Ọjọ́ mi yára ọkọ̀ ìhunṣọ lọ,

o di lílò àìní ìrètí.

7 Háà! Rántí afẹ́fẹ́ ni ̀mi;

ojú mi yóò padà rere mọ́.

8 Ojú ẹni ó mi, yóò mi mọ́;

ojú rẹ̀ tẹ̀ mọ́ra mi, èmi mọ́.

9 ìkùùkuu i túká, í lọ,

bẹ́̀ ni ẹni ń lọ ipò òkú yóò padà wa mọ́.

10 yóò padà sínú ilé rẹ̀ mọ́,

bẹ́̀ ipò rẹ̀ yóò mọ̀ ọn mọ́.

11 "Nítorí náà èmi yóò pa ẹnu mi mọ́,

èmi yóò máa sọ nínú ìrora ọkàn mi,

èmi yóò máa ṣe ìráhùn nínú kíkorò ọkàn mi.

12 Èmi a máa ṣe Òkun tàbí ̀búburú,

ìwọ fi ń yan olùṣọ́ mi?

13 Nígbà mo , ibùsùn mi yóò lára,

ìtẹ́ mi yóò ara mi fúyẹ́ pẹ̀.

14 Nígbà náà ni ìwọ fi àlá da yọ mi lénu mi,

ìwọ fi ìran òru dẹ́rùbà .

15 Bẹ́̀ ni ọkàn yàn láti fún pa

àti ikú ju ń láààyè ipò ara yìí lọ.

16 O mi, èmi le títí:

jọ̀wọ́ mi jẹ́, nítorí asán ni ọjọ́ mi.

17 7.17: Sm 8.4. "ni ènìyàn ìwọ o máa kókìkí rẹ̀?

Àti ìwọ ìbá fi gbé ọkàn rẹ e?

18 Àti ti ìwọ ó fi máa í bẹ̀ ́ ni òròòwúrọ̀,

ti ìwọ o máa dán an nígbàkígbà!

19 Yóò ti pẹ́ ìwọ ó fi sílẹ̀ lọ,

ìwọ o fi sílẹ̀ jẹ́́ títí èmi yóò fi itọ́ mi .

20 Èmi ti ṣẹ̀, ki èmi ó ṣe .

Ìwọ Olùsójú ènìyàn?

Èéṣe ìwọ fi fi ṣe àmì itasi níwájú rẹ,

bẹ́̀ ni èmi di ẹrẹ̀ wíwo fún ?

21 Èéṣe ìwọ dárí ìrékọjá mi jìn,

ìwọ ó àìṣedéédéé mi kúrò?

Ǹjẹ́ nísinsin yìí ni èmi ìbá sùn nínú erùpẹ̀,

ìwọ ìbá mi kiri òwúrọ̀, èmi ."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-