Publicidade

1 Crônicas 17

Ìlérí Ọlọ́run Dafidi

1 Lẹ́yìn ìgbà Dafidi ti fi ìdí kalẹ̀ sínú ààfin rẹ̀, ó sọ fún Natani wòlíì , "Èmi nìyí, ń gbé inú ààfin kedari nígbà àpótí ̀Olúwa lábẹ́ àgọ́."

2 Natani Dafidi lóhùn , "Ohunkóhun o lọ́kàn, ṣe é nítorí Ọlọ́run pẹ̀rẹ."

3 àṣálẹ́ ọjọ́ náà, ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Natani , :

4 "Lọ sọ fún ìránṣẹ́ mi Dafidi, Èyí ni ohun Olúwa : Ìwọ gbọdọ̀ kọ́ ilé fún mi láti máa gbé. 5 Èmi ì gbé nínú ilé láti ọjọ́ mo ti Israẹli jáde láti Ejibiti títí di òní yìí. Èmi ń lọ láti àgọ́ àgọ́ àti láti ibùgbé ibùgbé. 6 Ni ibi gbogbo mo ti gbogbo Israẹli rìn , ǹjẹ́ mo nǹkan kan ̀kan nínú àwọn adarí Israẹli, èmí pàṣẹ fún láti máa jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn àwọn ènìyàn mi, , "ṣe ̀yin fi kọ́ ilé a fi igi kedari kọ́ fún mi?" 

7 "Nígbà náà, sọ fún ìránṣẹ́ mi Dafidi , Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun : Èmi kúrò pápá oko tútù , àní kúrò lẹ́yìn agbo àgùntàn, ìwọ ó máa ṣe olórí àwọn ènìyàn mi Israẹli. 8 Èmi ti pẹ̀rẹ , ibikíbi ìwọ lọ, èmí ti gbogbo àwọn ̀rẹ kúrò níwájú rẹ. Nísinsin yìí Èmi yóò orúkọ rẹ ó dàbí orúkọ àwọn ènìyàn ńlá jùlọ ó ayé. 9 Èmi yóò pèsè ààyè kan fún àwọn ènìyàn mi Israẹli, wọn ó ilé tiwọn, a ṣe dààmú wọn mọ́. Àwọn ènìyàn búburú yóò ni wọ́n lára mọ́, gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe ìbẹ̀rẹ̀. 10 wọ́n ti ṣe láti ìgbà mo ti yan àwọn aṣáájú lórí àwọn ènìyàn mi Israẹli. Èmi pẹ̀yóò ṣẹ́gun gbogbo àwọn ̀yín.

" Èmi sọ fún yín Olúwa yóò kọ́ ilé kan fún yín, 11 nígbà ti ọjọ́ rẹ kọjá, ìwọ lọ láti lọ àwọn baba à rẹ, Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ sókè láti rọ́rẹ, ̀kan lára àwọn ọmọ tìrẹ, Èmi yóò fìdí ìjọba rẹ̀ kalẹ̀. 12 Òun ni ẹni yóò kọ́ ilé fún mi, èmi yóò fi ìdí ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ títí láé. 13 Èmi yóò jẹ́ baba rẹ̀, Òun yóò jẹ́ ọmọ mi. Èmi yóò ìfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ láéláé gẹ́gẹ́ mo ṣe un kúrò lọ́dọ̀ àwọn aṣáájú rẹ̀. 14 Èmi yóò gbé e ka orí ilé mi àti ìjọba mi títí láé; ìtẹ́ rẹ̀ ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí láé.’ "

15 Natani ròyìn fún Dafidi gbogbo àwọn ̀rọ̀ ti ìfihàn .

Àdúrà Dafidi

16 Nígbà náà, ọba Dafidi wọlé lọ, ó jókòó níwájú Olúwa ó ,

"Ta ni èmi, Olúwa Ọlọ́run, àti ki ni ìdílé mi, ìwọ mi ibí? 17 Pẹ̀ẹni èyí lójú rẹ, Ọlọ́run, ìwọ ti sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ iwájú ilé ìránṣẹ́ rẹ. Ìwọ ti ẹni èmi ni ẹni gbígbéga láàrín àwọn ọkùnrin Olúwa Ọlọ́run.

18 "ni ohun Dafidi tún sọ nítorí ọlá o fún ìránṣẹ́ rẹ? Nítorí ìwọ mọ ìránṣẹ́ rẹ, 19 Olúwa. Nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ àti gẹ́gẹ́ àṣẹ rẹ, ìwọ ti ṣe ohun ńlá yìí àti láti fi gbogbo ìlérí ńlá yìí hàn.

20 "ẹnìkan rẹ Olúwa, Ọlọ́run kan àfi ìwọ, gẹ́gẹ́ à ti gbọ́ pẹ̀etí ara wa. 21 Pẹ̀ta ni ó dàbí àwọn ènìyàn rẹ Israẹliorílẹ̀-èdè kan ayé, Ọlọ́run jáde lọ láti ra àwọn ènìyàn kan padà fún ara rẹ̀, àti láti ṣe orúkọ fún ara à rẹ, àti láti ṣe ohun ńlá àti ọwọ́ ìyanu nípa lílé àwọn orílẹ̀-èdè kúrò níwájú àwọn ènìyàn rẹ̀, ẹni ó gbàlà láti Ejibiti? 22 Ìwọ ṣe àwọn ènìyàn rẹ Israẹli tìrẹ láéláé ìwọ Olúwa ti di Ọlọ́run wọn.

23 "Nísinsin yìí, Olúwa, jẹ́ ìlérí ìwọ ti ṣe fún ìránṣẹ́ rẹ àti ilé rẹ̀ di fífi ìdí múlẹ̀ títí láé. Ṣe gẹ́gẹ́ o ti ṣe ìlérí. 24 ó di fífi ìdí múlẹ̀ àti orúkọ rẹ di gbígbéga títí láé. Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin yóò , Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ni Ọlọ́run Israẹli.Ilé ìránṣẹ́ rẹ Dafidi ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níwájú rẹ.

25 "Ìwọ, Ọlọ́run mi, ti fihan ìránṣẹ́ rẹ , ìwọ yóò kọ́ ilé fún un. Bẹ́̀ ni ìránṣẹ́ rẹ ti ìgboyà láti gbàdúrà . 26 Olúwa, ìwọ ni Ọlọ́run. Ìwọ ti fi ìlérí dídára yìí fún ìránṣẹ́ rẹ. 27 Nísinsin yìí ó ti tẹ́ lọ́rùn láti bùkún ilé ìránṣẹ́ rẹ ó tẹ̀síwájú ojú rẹ; nítorí ìwọ, Olúwa, ti bùkún un, a ó bùkún un títí láéláé."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-