Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 20

Dafidi ṣẹ́gun Rabba

1 20.1: 2Sa 11.1. 20.1-3: 2Sa 12.26-31. àkókò àkọ́rọ̀ òjò, ni ìgbà àwọn ọba lọ ogun, Joabu ṣamọ̀àwọn ̀wọ́ ọmọ-ogun. Ó fi ilẹ̀ àwọn ará Ammoni ṣòfò. Ó lọ ̀dọ̀ Rabba. Ó fi ogun dúró í. Ṣùgbọ́n Dafidi dúró Jerusalẹmu Joabu kọlu Rabba, ó fi sílẹ̀ ìparun. 2 Dafidi adé kúrò lórí àwọn ọba wọn ìwọ̀n rẹ̀ dàbí i tálẹ́ǹtì wúrà, a ó jọ pẹ̀àwọn òkúta iyebíye. A gbé e ka orí Dafidi. Ó ̀pọ̀ ìkógun láti ìlú ńlá náà. 3 Ó gbogbo àwọn ènìyàn ó ibẹ̀ jáde, ó fi iṣẹ́ wọn lọ́wọ́ láti ṣiṣẹ́ pẹ̀ayùn àti ìtulẹ̀ onírin àti àáké. Dafidi ṣe eléyìí gbogbo àwọn ará ìlú Ammoni. Nígbà náà, Dafidi àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ padà Jerusalẹmu.

Ogun pẹ̀àwọn ará Filistini

4 20.4-8: 2Sa 21.18-22. ̀yìn èyí ni ogun bẹ́ sílẹ̀ Geseri pẹ̀àwọn ará Filistini, àkókò yìí ni Sibekai ará Huṣati pa Sipai, ̀kan lára àwọn ọmọ Refaimu, àti àwọn ará Filistini ni a ṣẹ́gun.

5 Nínú ogun mìíràn pẹ̀àwọn ará Filistini, Elhanani ọmọ Jairi pa Lahmi arákùnrin Goliati ará Gitti, ẹni ti ó ̀kọ̀ kan ó dàbí ̀ahunṣọ.

6 Síbẹ̀síbẹ̀ nínú ogun mìíràn, ó wáyé Gati, ọkùnrin títóbi kan ó ìka mẹ́ọwọ́ rẹ̀ pẹ̀ìka mẹ́ẹsẹ̀ rẹ̀ mẹ́rìnlélógún lápapọ̀. Òun pẹ̀láti Rafa. 7 Nígbà ó fi Israẹli ṣẹ̀sín, Jonatani ọmọ Ṣimea, arákùnrin Dafidi pa á.

8 Wọ̀nyí ni ìran ọmọ Rafa Gati, wọ́n ṣubú ọwọ́ Dafidi àti àwọn ọkùnrin rẹ̀.

Veja também