Publicidade

1 Crônicas 28

Àwọn èrò Dafidi lórí ilé Olúwa

1 Dafidi pe gbogbo àwọn oníṣẹ́ ti Israẹli láti péjọ Jerusalẹmu. Àwọn ìjòyè lórí àwọn ̀, àwọn alákòóso ìpín nínú iṣẹ́ ọba, àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ̀rọ̀̀rún àti àwọn oníṣẹ́ ó ìdí bíbojútó gbogbo àwọn ẹrù àti ohun ̀sìn ó jẹ́ ti ọba àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀ààfin àwọn oníṣẹ́ ààfin, àwọn ọkùnrin alágbára àti gbogbo àwọn ògbójú jagunjagun lápapọ̀.

2 Ọba Dafidi dìde dúró ẹsẹ̀ rẹ̀, o , "Fetísílẹ̀ mi, ̀yin ará mi àti ̀yin ènìyàn mi. Èmi o ni lọ́kàn mi láti kọ́ ilé gẹ́gẹ́ ibi ìsinmi fún àpótí ̀Olúwa fún àpótí ìtìsẹ̀ Ọlọ́run wa, èmi gbèrò láti kọ́ . 3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún mi , Ìwọ gbọdọ̀ kọ́ ilé fún orúkọ mi, nítorí ìwọ jẹ́ jagunjagun, ìwọ ti tàjẹ̀ sílẹ̀.’

4 "Síbẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli yàn láti gbogbo ìdílé láti jẹ́ ọba lórí Israẹli, títí láé. Ó yan Juda gẹ́gẹ́ olórí, àti láti ilé Juda, ó yan ìdílé mi, àti láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ baba à , ó tẹ́ lọ́rùn láti fi ṣe ọba lórí gbogbo Israẹli. 5 Nínú gbogbo àwọn ọmọ mi pẹ̀Olúwa ti fún mi púpọ̀, ó ti yan ọmọ mi Solomoni láti jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba ti Olúwa lórí Israẹli. 6 Ó fún mi , Solomoni ọmọ rẹ ni ẹni yóò kọ́ ilé mi àti àwọn ààfin mi, nítorí èmi ti yàn án láti ṣe ọmọ mi èmi yóò jẹ́ baba a rẹ̀. 7 Èmi yóò fi ìdí ìjọba rẹ̀ kalẹ̀ títí láé kọ̀ láti gbé àṣẹ àti òfin mi jáde, gẹ́gẹ́ a ti ṣe é àsìkò yìí.

8 "Bẹ́̀ ni, nísinsin yìí, èmi pàṣẹ fún ojú gbogbo Israẹli àti ti ìpéjọpọ̀ Olúwa, àti etí ìgbọ́ Ọlọ́run wa. Ṣọ́ra o tẹ̀gbogbo òfin Olúwa Ọlọ́run rẹ ìwọ ó le jogún ilẹ̀ dáradára yìí, o un lọ síwájú gẹ́gẹ́ ogún rẹ fún àwọn ìran ọmọ rẹ títí láé.

9 "Àti ìwọ, ọmọ mi Solomoni, rántí Ọlọ́run baba à rẹ, o sìn ín pẹ̀tọkàntọkàn pẹ̀ìfọkànsí pẹ̀ọkàn ó , nítorí Olúwa ṣàwárí gbogbo ọkàn ó mọ gbogbo èrò. ìwọ a, ìwọ yóò i; ṣùgbọ́n ìwọ kọ̀ ́ sílẹ̀, òun yóò kọ̀ ́ títí láé. 10 Gbèrò báyìí nítorí Olúwa ti yàn ́ láti kọ́ ilé Olúwa gẹ́gẹ́ ilé a mímọ́ fún Olúwa. Jẹ́ alágbára ó ṣe iṣẹ́ náà."

11 Nígbà náà ni Dafidi fi àpẹẹrẹ fún Solomoni ọmọ rẹ̀ ti ìloro àti ti ilé Olúwa náà, kíkọ́ rẹ̀, àti ti ibi ìṣúra rẹ̀, àti ti iyàrá òkè rẹ̀, àti ti ìyẹ̀rẹ̀ àti ti ibùjókòó àánú. 12 Ó fún un àwọn ètò gbogbo èyí ̀ti fi ọkàn rẹ̀ fún ti ààfin ilé Olúwa àti gbogbo yàrá ó yíká fún ìṣúra ilé Ọlọ́run àti fún ìṣúra fún ohun yíyà sọ́tọ̀. 13 Ó fún un àwọn ìlànà fún ìpín ti àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi àti fún gbogbo iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa àti fún gbogbo ohun èlò wọn ó nínú ìsìn rẹ̀. 14 Ó yàn ìwọ̀n wúrà fún gbogbo ohun èlò wúrà a ó níbi oríṣìí ìsìn, àti ìwọ̀n fàdákà fún gbogbo ohun èlò fàdákà a ó fún oríṣìí ìsìn, 15 ìwọ̀n wúrà fún ìdúró fìtílà àti fìtílà wọn, fún ìwọ̀n fún ̀kọ̀̀kan ìdúró fìtílà àti fìtílà wọn; àti ìwọ̀n fàdákà ìdúró fìtílà fàdákà àti àwọn fìtílà rẹ̀, gẹ́gẹ́ ìlò ti gbogbo ìdúró fìtílà. 16 Ìwọ̀n ti wúrà fun tábìlì, tábìlì fún àkàrà a sọ́tọ̀; ìwọ̀n fàdákà fún àwọn tábìlì fàdákà; 17 ìwọ̀n kìkì wúrà fún àwọn àmúga ìjẹun, àwọn ìbùwọ́n ọpọ́n àti àwọn ìkòkò ìpọnmi; ìwọ̀n wúrà fún gbogbo àwopọ̀kọ́ fàdákà; 18 àti ìwọ̀n ìdá wúrà fún pẹpẹ tùràrí ó fún un ètò fún kẹ̀kẹ́, ìyẹn ni àwọn ìdúró kérúbù wúrà wọ́n tan iye wọn , wọ́n bo àpótí ̀Olúwa.

19 "Gbogbo èyí," ni Dafidi , "Èmi kíkọ sílẹ̀ láti ọwọ́ Olúwa sórí mi, ó fún ìmọ̀ nínú gbogbo iṣẹ́ ètò yìí."

20 Dafidi tún sọ fún Solomoni ọmọ rẹ̀ , "Jẹ́ alágbára o gbóyà, o ṣe iṣẹ́ náà. ṣe bẹ̀tàbí dààmú, nítorí Olúwa Ọlọ́run, Ọlọ́run mi, pẹ̀rẹ. Òun yóò kule tàbí kọ sílẹ̀ títí gbogbo iṣẹ́ fún ìsìn ti ilé Olúwa yóò fi parí. 21 Ìpín àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi ti ṣetán fún gbogbo iṣẹ́ ilé Olúwa. Gbogbo ọkùnrin ó ìfẹ́ i ó òye oríṣìíríṣìí iṣẹ́. Yóò ràn ́ lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ náà. Àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ènìyàn yóò gbọ́rọ̀ gbogbo àṣẹ rẹ."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-