Publicidade

2 Reis 23

Josiah sọ májẹ̀dọ̀tun

1 Nígbà náà ọba pe gbogbo àwọn àgbàgbà Juda àti Jerusalẹmu jọ. 2 Ó gòkè lọ ilé Olúwa pẹ̀àwọn ọkùnrin Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu, àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíìgbogbo àwọn ènìyàn láti ibi kéékèèké ńlá. Ó á etí ìgbọ́ wọn, gbogbo ̀rọ̀ ó nínú ìwé májẹ̀, a ti nínú ilé Olúwa. 3 Ọba dúró lẹ́bàá òpó, ó sọ májẹ̀di tuntun níwájú Olúwa, láti tẹ̀Olúwa àti láti pa òfin rẹ̀ mọ́, ìlànà àti òfin pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ̀ àti gbogbo ̀rẹ̀, àti láti ṣe ìwádìí àwọn ̀rọ̀ májẹ̀a kọ sínú ìwé yìí. Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn ṣèlérí fúnra wọn májẹ̀náà.

4 23.4-20: 2Ki 34.3-7. Ọba pàṣẹ fún Hilkiah olórí àlùfáà àti àwọn, àlùfáà ó tẹ̀e ipò àti àwọn olùṣọ́láti yọ kúrò nínú ilé Olúwa gbogbo ohun èlò a ṣe fún Baali àti Aṣerah àti gbogbo ẹgbẹ́ ogun ̀run. Ó sun wọ́n ìta Jerusalẹmu pápá àfonífojì Kidironi. Ó eérú wọn jọ Beteli. 5 Ó kúrò pẹ̀àwọn àlùfáà abọ̀rìṣà a yàn láti ọwọ́ ọba Juda láti sun tùràrí ibi gíga ti ìlú Juda àti àwọn ó Jerusalẹmu . Àwọn ó ń sun tùràrí Baali, oòrùn àti òṣùpá, àwọn àmì ìràwọ̀ àti gbogbo ẹgbẹ́ ogun ̀run. 6 Ó ère òrìṣà Aṣerah láti ilé Olúwa àfonífojì Kidironi ìta Jerusalẹmu, ó sun wọ́n níbẹ̀. Ó lọ̀ ́ àtíkè ó fọ́n eruku náà sórí isà òkú àwọn ènìyàn ó wọ́pọ̀. 7 Ó ibùgbé àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà lulẹ̀. ó nínú ilé Olúwa àti ibi àwọn obìnrin ń ṣe iṣẹ́ aṣọ híhun fún òrìṣà Aṣerah.

8 Josiah gbogbo àwọn àlùfáà láti àwọn ìlú Juda ó ba ibi mímọ́ wọ̀n-ọn-nì jẹ́ láti Geba Beerṣeba, níbi àwọn àlùfáà ti sun tùràrí. Ó àwọn ojúbọ lulẹ̀ ẹnu ìlẹ̀kùnẹnu-ọ̀àbáwọlé ti Joṣua, baálẹ̀ ìlú ńlá ó apá òsì ẹnu ìlẹ̀kùn ìlú ńlá. 9 ó tilẹ̀ jẹ́ , àwọn àlùfáà ibi gíga jọ́sìn ibi pẹpẹ Olúwa Jerusalẹmu, wọ́n jẹ nínú àkàrà aláìwú pẹ̀àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ wọn.

10 Ó ba ohun mímọ́ Tofeti jẹ́, ó àfonífojì Beni-Hinnomu, bẹ́̀ ni ẹnìkan ó ó fún ẹbọ rírú fún ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tàbí ọmọ rẹ̀ obìnrin nínú iná Moleki. 11 Ó kúrò láti ẹnu-ọ̀àbáwọlé ilé Olúwa, àwọn ẹṣin àwọn ọba Juda ti sọ́tọ̀ oòrùn náà. Wọ́n nínú ilé ẹjọ́ lẹ́bàá yàrá oníṣẹ́ orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Natani-Meleki. Josiah sun àwọn kẹ̀kẹ́ a sọ́tọ̀ fún oòrùn.

12 Ó o palẹ̀ pẹpẹ àwọn ọba Juda ti wọ́n gbé dúró orí òrùlé lẹ́bàá yàrá òkè ti Ahasi pẹ̀àwọn pẹpẹ Manase ti kọ́ nínú ilé ẹjọ́ méjèèjì ilé Olúwa. Ó ṣí wọn kúrò níbẹ̀, ó fọ́ wọn wẹ́wẹ́. Ó da ekuru wọn sínú àfonífojì Kidironi. 13 Ọba pẹ̀ba ohun mímọ́ àwọn ibi gíga jẹ́ ó ìhà ìlà-oòrùn Jerusalẹmu ìhà gúúsù ti òkè ìbàjẹ́—èyí Solomoni ọba Israẹli ti kọ́ fún Aṣtoreti ọlọ́run ìríra àwọn ará Sidoni, fún Kemoṣi ọlọ́run ìríra àwọn ará Moabu àti fún Moleki, ọlọ́run ìríra àwọn ènìyàn Ammoni. 14 Josiah fọ́ òkúta yíyà sọ́tọ̀, ó ère Aṣerah lulẹ̀. Ó bo ̀gbẹ̀gbẹ́ rẹ̀ pẹ̀egungun ènìyàn.

15 Àní pẹpẹ ó Beteli ibi gíga Jeroboamu ọmọ Nebati . ó ti fa Israẹli láti ṣẹ̀, àní pẹpẹ náà àti ibi gíga ó fọ́ túútúú. Ó àwọn ibi gíga, ó lọ̀ ́ ̀, ó sun ère Aṣerah pẹ̀. 16 Nígbà náà, Josiah yíká, nígbà ó àwọn isà òkú ó níbẹ̀ ̀òkè, ó yọ egungun kúrò lára wọn, ó wọn lórí pẹpẹ láti sọ ́ di èérí ìbámu pẹ̀̀rọ̀ Olúwa a ti kéde láti ̀dọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ó ti àwọn nǹkan wọ̀nyí tẹ́lẹ̀.

17 Ọba béèrè , "ni ọwọ̀n isà òkú yẹn mo ?"

Àwọn ọkùnrin ìlú ńlá , "Ó sàmì isà òkú ènìyàn Ọlọ́run ó láti Juda, ó kéde ìdojúkọ pẹpẹ Beteli, ohun kan wọ̀nyí ìwọ ti ṣe wọn."

18 "Fi sílẹ̀ nìkan," Ó . "ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó da àwọn egungun rẹ̀ láàmú." Bẹ́̀ ni wọ́n egungun rẹ̀ àti ti àwọn wòlíì ó láti Samaria.

19 Gẹ́gẹ́ ó ti ṣe Beteli, Josiah kúrò, ó ba gbogbo ojúbọ òrìṣà ti ibi gíga jẹ́, àwọn ọba Israẹli ti kọ́ àwọn ìlú Samaria, ó ti Olúwa bínú. 20 Josiah dúńbú gbogbo àwọn àlùfáà ibi gíga lórí pẹpẹ. Ó sun egungun ènìyàn lórí wọn. Nígbà náà, ó padà lọ Jerusalẹmu.

21 23.21-23: 2Ki 35.1-19. Ọba pàṣẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn , "ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá Olúwa Ọlọ́run yín, gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ inú ìwé májẹ̀yìí." 22 í ṣe láti ọjọ́ àwọn Juda ó tọ́ Israẹli, gbogbo àwọn ọjọ́ àwọn ọba Israẹli àti àwọn ọba Juda. Ṣé wọ́n ti ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá . 23 Ṣùgbọ́n ọdún kejìdínlógún ọba Josiah, àjọ ìrékọjá yìí ni a ṣe ìrántí Olúwa Jerusalẹmu.

24 Síwájú , Josiah àwọn oṣó àti àwọn ̀àwọn ìdílé, àti àwọn òrìṣà àti gbogbo àwọn nǹkan ìríra a Juda àti Jerusalẹmu. Èyí ni ó ṣe ó le è ̀rọ̀ òfin náà ṣe ti òfin a kọ sínú ìwé Hilkiah àlùfáà ti nínú ilé Olúwa. 25 ọba kankan níwájú tàbí lẹ́yìn Josiah ó dàbí rẹ̀, ó padà olúwa tinútinú àti gẹ́gẹ́ ó ti ṣe tọkàntọkàn pẹ̀gbogbo ̀i rẹ̀, pẹ̀gbogbo agbára rẹ̀ ìbámu pẹ̀gbogbo òfin Mose.

26 ó ti ó Olúwa yípadà kúrò nínú ìmúná ìbínú ńlá rẹ̀ ó Juda, nítorí gbogbo èyí Manase ti ṣe láti un bínú. 27 Bẹ́̀ ni Olúwa , "Èmi yóò Juda kúrò pẹ̀níwájú mi, mo ti Israẹli, èmi yóò Jerusalẹmu, ìlú ńlá mo yàn àti ilé Olúwa yìí, nípa èyí mo sọ, Níbẹ̀ ni orúkọ mi yóò ?’ "

28 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Josiah, àti gbogbo ohun ó ṣe, ṣé a kọ wọ́n inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda?

29 Nígbà Josiah jẹ́ ọba, Farao Neko ọba Ejibiti gòkè lọ odò Eufurate láti lọ ran ọba Asiria lọ́wọ́. Ọba Josiah jáde lọ láti lọ a pàdé lójú ogun ṣùgbọ́n Neko dojúkọ ́, ó pa á Megido. 30 23.30-34: 2Ki 36.1-4.Ìránṣẹ́ Josiah gbé ara rẹ̀ nínú kẹ̀kẹ́ láti Megido Jerusalẹmu ó sin ín sínú isà òkú rẹ̀. Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà Jehoahasi ọmọ Josiah. Ó fi àmì òróró yàn án, ó ṣe é ọba ipò baba a rẹ̀.

Jehoahasi ọba Juda

31 Jehoahasi jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélógún nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Hamutali ọmọbìnrin Jeremiah; ó láti Libina. 32 Ó ṣe búburú lójú Olúwa gẹ́gẹ́ baba a rẹ̀ ti ṣe. 33 Farao Neko fi inú ìdè Ribla ilẹ̀ Hamati, ó ba à jẹ ọba Jerusalẹmu. Ó tan Juda jẹ fun iye ìwọ̀n ẹgbẹ̀rin tálẹ́ǹtì wúrà kan. 34 Farao Neko ṣe Eliakimu ọmọ Josiah ọba ipò baba rẹ̀ Josiah. Ó orúkọ Eliakimu padà Jehoiakimu. Ṣùgbọ́n ó Jehoahasi, ó gbé e lọ Ejibiti, níbẹ̀ ni ó . 35 Jehoiakimu san fún Farao Neko fàdákà àti wúrà ó béèrè. Láti ṣe bẹ́̀, ó bu owó òde fún ilẹ̀ náà láti san, ó fi agbára gba fàdákà àti wúrà láti ọwọ́ àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà ìbámu pẹ̀iye a pín.

Jehoiakimu ọba Juda

36 23.36–24.6: 2Ki 36.5-8. Jehoiakimu jẹ́ ẹni ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlá orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sebida ọmọbìnrin Pedaiah ó láti Ruma. 37 Ó ṣe búburú lójú Olúwa gẹ́gẹ́ baba a rẹ̀ ti ṣe.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-