Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Reis 4

32 Nígbà Eliṣa inú ilé, níbẹ̀ ni òkú ọmọ ọkùnrin náà dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn. 33 Ó wọ ilé, ó ti ìlẹ̀kùn mọ́ àwọn méjèèjì ó gbàdúrà Olúwa. 34 Nígbà náà ó orí ibùsùn, ó sùn sórí ọmọ ọkùnrin náà, ẹnu ẹnu, ojú ojú, ọwọ́ ọwọ́. Gẹ́gẹ́ ó ti ara rẹ̀ lórí rẹ̀, ara ọmọ náà gbóná. 35 Eliṣa yípadà lọ, ó rìn padà ó jáde sínú ilé nígbà náà ó padà orí ibùsùn ó tún e ̀̀kan i. Ọmọ ọkùnrin náà sín ìgbà méje ó ṣí ojú rẹ̀.

Veja também