Pular para o conteúdo
Publicidade

Números 35

Ìlú fún àwọn ọmọ Lefi

1 35.1-8: Le 25.32-34; Jo 21.1-42. Lórí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu Jordani ó rékọjá láti Jeriko, Olúwa sọ fún Mose , 2 "Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli láti fún àwọn Lefi ilẹ̀ láti gbé lára ogún àwọn ọmọ Israẹli yóò jogún. fún wọn ilẹ̀ lára pápá oko tútù, káàkiri ìlú. 3 Nígbà náà, wọn yóò ìlú wọn yóò gbé àti ilẹ̀ pápá oko tútù fún ẹran ̀sìn, ̀wọ́ ẹran pẹ̀gbogbo ìní wọn.

4 "Ilẹ̀ pápá oko tútù káàkiri ìlú ó fi fún àwọn ọmọ Lefi, wíwọ̀n rẹ̀ yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún ìgbọ̀nwọ́ (1,500 ẹsẹ̀ bàtà) láti ògiri ìlú náà. 5 Lẹ́yìn ìlú náà, wọn ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ìgbọ̀nwọ́ lápá ibi ìhà ìlà-oòrùn, ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ẹsẹ̀ bàtà ìhà gúúsù, ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ìhà ìwọ̀-oòrùn àti ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ìhà àríwá, ìlú náà àárín. Wọn yóò agbègbè yìí gẹ́gẹ́ ilẹ̀ pápá oko tútù fún ìlú náà.

Ìlú ààbò

6 35.6,9-34: De 19.1-13. "Mẹ́lára ìlú fún àwọn ọmọ Lefi yóò jẹ́ ìlú ààbò, ẹni ó pa ènìyàn yóò . àfikún, fún wọn méjìlélógójì ìlú i. 7 gbogbo rẹ̀, fún àwọn ọmọ Lefi méjìdínláàádọ́ta ìlú lápapọ̀ pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù wọn. 8 Ìlú fún àwọn ọmọ Lefi láti ara ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli jogún, olúkúlùkù ó fi nínú ìlú rẹ̀ fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìní rẹ̀ ó . Gba púpọ̀ lọ́wọ́ ̀ó púpọ̀ àti díẹ̀ lọ́wọ́ ̀ó díẹ̀."

9 35.9-28: De 19.2-4; Jo 20.1-9. Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , 10 "Sọ̀rọ̀ àwọn ọmọ Israẹli, o sọ fún wọn: Nígbà rékọjá odò Jordani Kenaani, 11 yan àwọn ìlú kan láti jẹ́ gẹ́gẹ́ ìlú ààbò fún yín, apani pa ènìyàn àìmọ̀ máa sálọ síbẹ̀. 12 Wọn yóò jẹ́ ibi ìsásí kúrò lọ́wọ́ olùgbẹ̀san, ẹni a fi ̀sùn ìpànìyàn kàn ba à ó dúró níwájú àwọn ìjọ àwọn ènìyàn ìdájọ́. 13 Mẹ́nínú ìlú ó fi fún wọn yóò jẹ́ ìlú ààbò fún yín. 14 Yan ìlú mẹ́ta ìhà ti Jordani, yan ìlú mẹ́ta ìhà Kenaani yóò máa jẹ́ ìlú ìsásí. 15 Ìlú mẹ́yìí yóò jẹ́ ìlú ìsásí fún àwọn ọmọ Israẹli, fún àjèjì àti ẹnikẹ́ni ó ń gbé láàrín wọn, ẹnikẹ́ni ó pa ènìyàn àìmọ̀ sálọ síbẹ̀.

16 " ọkùnrin kan fi ohun èlò irin lu ènìyàn ó , apànìyàn ni, pípa ni a ó pa, apànìyàn náà. 17 Tàbí ènìyàn òkúta ó pa ènìyàn lọ́wọ́ ó fi lu ènìyàn, ó , apànìyàn ni, pípa ni a ó pa apànìyàn náà. 18 Tàbí ènìyàn ohun èlò igi ọwọ́ rẹ̀ ó lẹ̀ ́ pa ènìyàn, ó fi lu ènìyàn, ó , apànìyàn ni; pípa a ó pa apànìyàn náà. 19 Olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ yóò pa apànìyàn náà; ó a, yóò pa á. 20 ẹnikẹ́ni ó ń yan odì pẹ̀ìríra ẹlòmíràn tàbí ju nǹkan i pẹ̀èrò, ó . 21 Tàbí pẹ̀ìjà gbangba ú pẹ̀ìkùùkuu ó , pípa ni a ó pa ẹni bẹ́̀; apànìyàn ni. Olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ yóò pa apànìyàn náà ó a.

22 " Ṣùgbọ́n ó fi nǹkan gún un lójijì láìṣọ̀ta, tàbí ó sọ ohunkóhun ú láìmọ̀-́n-mọ̀ ṣe 23 tàbí, láìri, ju òkúta ó pa á, ó , nígbà í ṣe ̀rẹ̀, láti ṣe é léṣe. 24 Àwọn àpéjọ gbọdọ̀ dájọ́ láàrín rẹ̀ àti olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ gẹ́gẹ́ ìlànà. 25 Àpéjọ gbọdọ̀ ààbò bo ẹni a fi ̀sùn ìpànìyàn kàn, a rán an padà lọ ìlú ìsásí ó ti . Ó gbọdọ̀ dúró níbẹ̀ títí di ìgbà olórí àlùfáà , ẹni a fi àmì òróró yàn.

26 " Ṣùgbọ́n ti ẹni a fi sùn kan jáde kọjá ààlà ìlú ìsásí ó . 27 olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ ri ìta ìlú náà, olùgbẹ̀san pa ẹni a fi ̀sùn kàn láìjẹ̀bi ̀sùn ìpànìyàn. 28 Ẹni a fi ̀sùn kàn gbọdọ̀ dúró nínú ìlú ìsásí títí di ìgbà olórí àlùfáà ; lẹ́yìn ikú olórí àlùfáà, ni ó padà ibi dúkìá rẹ̀ .

29 " Wọ̀nyí ni ó jẹ́ ìlànà ìdájọ́ fún yín ìran yín ń bọ̀, ibikíbi ń gbé.

30 35.30: De 17.6; 19.15. " Ẹnikẹ́ni ó pa ènìyàn gbọdọ̀ gẹ́gẹ́ apànìyàn lórí ìjẹ́rìí àwọn ènìyàn. Ṣùgbọ́n ẹlẹ́rìí kan ṣoṣo. yóò jẹ́rìí ẹnìkan láti pa.

31 " ṣe gba ohun ìràpadà fún ̀apànìyàn, ó jẹ̀bi ó . Ṣùgbọ́n pípa ni a pa á.

32 " ṣe gba ìràsílẹ̀ fún ẹnikẹ́ni ó lọ ìlú ìsásí, pe ó padà máa gbé ilẹ̀ tirẹ̀ ó di ìgbà ikú olórí àlùfáà.

33 " ṣe sọ ilẹ̀ di àìmọ́. Ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sọ ilẹ̀ náà di àìmọ́. Àtúnṣe yóò fún ilẹ̀ a ti ta ̀jẹ̀ lórí, àyàfi ̀jẹ̀ ẹni ó ta á sílẹ̀. 34 ṣe sọ di àìmọ́, ilẹ̀ ń gbé, àti èyí mo ń gbé, nítorí Èmi Olúwa ń gbé láàrín àwọn ọmọ Israẹli.’ "

Veja também