Pular para o conteúdo
Publicidade

Números 5

Wíwà mímọ́ ibùdó

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 5.2,3: Nu 12.14,15."Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli wọn ó ẹnikẹ́ni ̀tẹ̀, ìtújáde ara oríṣìíríṣìí tàbí ẹni jẹ́ aláìmọ́ nípa fífọwọ́ kan òkú. 3 Irú ẹni bẹ́̀ yálà ọkùnrin tàbí obìnrin, wọn jáde kúrò nínú ibùdó wọn ba à ba ibùdó wọn jẹ́ níbi èmi ń gbé láàrín wọn." 4 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe bẹ́̀; wọ́n wọn jáde kúrò nínú ibùdó. Wọn ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ fún Mose.

Ìjẹ́wọ́ àti àtúnṣe

5 5.5-8: El 22.7-15; Le 6.1-7. Olúwa sọ fún Mose , 6 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli: Nígbà ọkùnrin kan tàbí obìnrin kan ṣẹ̀ ara wọn lọ́kan tàbí òmíràn, wọ́n ṣe àìṣòótọ́ Olúwa, ẹni náà jẹ̀bi. 7 Ó gbọdọ̀ jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ ó sẹ̀. Ó gbọdọ̀ san ̀san rẹ̀ ojú owó, ó fi ìdámárùn-ún rẹ̀ e, ó fi fún ẹni òun jẹ̀bi rẹ̀. 8 Ṣùgbọ́n irú ẹni bẹ́̀ ìbátan ó súnmọ́ ọn ó ṣe àtúnṣe àṣìṣe rẹ̀ náà fún, àtúnṣe náà jẹ́ ti Olúwa, gbọdọ̀ ko fún àlùfáà pẹ̀àgbò a fi ṣe ètùtù fún ẹni náà. 9 Gbogbo ọrẹ ohun mímọ́ àwọn ọmọ Israẹli fún àlùfáà jẹ́ tirẹ̀. 10 Ọrẹ ohun mímọ́ ẹnìkọ̀̀kan jẹ́ ti òun nìkan, ṣùgbọ́n ohunkóhun fún àlùfáà yóò jẹ́ ti àlùfáà.’ "

Àyẹ̀fún aláìṣòótọ́ ìyàwó

11 Olúwa sọ fún Mose , 12 "àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀ o sọ fún wọn , ìyàwó ọkùnrin kan yapa ṣe àìṣòótọ́ i, 13 nípa mímú ọkùnrin mìíràn a lòpọ̀ ó fi èyí pamọ́ fún ọkọ rẹ̀, a si gbá a nínú ìwà àìmọ́ rẹ̀ (nítorí ẹlẹ́rìí àti wọn a mọ́ nígbà ó ń dẹ́ṣẹ̀ náà). 14 Ṣùgbọ́n ̀owú jíjẹ ọkọ rẹ̀ bi ó ń funra ìyàwó rẹ̀ yìí ìyàwó rẹ̀ àìmọ́ nítòótọ́, tàbí ̀owú ọkùnrin kan ń jowú ìyàwó rẹ̀ ó tilẹ̀ jẹ́ ó mímọ́, 15 nígbà náà ni ọkùnrin yìí yóò ìyàwó rẹ̀ lọ sọ́dọ̀ àlùfáà. Ọkùnrin náà yóò ọrẹ a yàn fún obìnrin náà, ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n efa ìyẹ̀fun barle. gbọdọ̀ da òróró i, bẹ́̀ ni gbọdọ̀ fi tùràrí dídùn i nítorí ẹbọ ohun jíjẹ fún owú ni, èyí ti n ̀ṣẹ̀ ìrántí.

16 " Àlùfáà yóò un síwájú Olúwa. 17 Àlùfáà yóò bu erùpẹ̀ ilẹ̀ àgọ́ sínú omi mímọ́ láti ìkòkò amọ̀. 18 Lẹ́yìn èyí, àlùfáà yóò obìnrin náà dúró níwájú Olúwa yóò irun orí obìnrin náà e lọ́wọ́, èyí ni ẹbọ ohun jíjẹ ti owú, àlùfáà fúnra rẹ̀ yóò gbé omi kíkorò ń ègún lọ́wọ́. 19 Àlùfáà yóò obìnrin náà búra, yóò , "ọkùnrin mìíràn lòpọ̀, ó yapa, o di aláìmọ́ níwọ̀n ìgbà ó lábẹ́ àṣẹ ọkọ rẹ̀, a jẹ́ omi kíkorò ń ègún yìí ṣe ́ níbi. 20 Ṣùgbọ́n ìwọ ti yapa kúrò lọ́dọ̀ ọkọ rẹ, o ti ba ara rẹ jẹ́ nípa jíjẹ́ ọkùnrin í ṣe ọkọ rẹ lòpọ̀," 21 nígbà náà ni àlùfáà yóò obìnrin náà búra, yóò sọ fún obìnrin náà , "Olúwa sọ ́ di ẹni ègún àti ẹni ìbáwí láàrín àwọn ènìyàn rẹ nípa mímú itan rẹ jẹrà, ikùn rẹ̀ . 22 Ǹjẹ́ omi yìí ń ègún wọ inú ara rẹ, ó ikùn rẹ̀ , ó itan rẹ̀ jẹrà dànù."

" Obìnrin náà yóò , "Àmín. Bẹ́̀ ni ."

23 " Nígbà náà ni àlùfáà yóò kọ ègún yìí sínú ìwé kíká, yóò sìn ín sínú omi kíkorò náà. 24 Àlùfáà yóò obìnrin náà mu omi kíkorò ń ègún yìí, omi náà yóò wọ inú rẹ̀ yóò fa ìrora kíkorò fún obìnrin náà ó jẹ̀bi. 25 Àlùfáà yóò gba ọrẹ ohun jíjẹ owú náà lọ́wọ́ rẹ̀, yóò í síwájú Olúwa, yóò iná sórí pẹpẹ. 26 Àlùfáà yóò bu ̀kúnwọ́ kan nínú ọrẹ ohun jíjẹ náà, yóò sun ún lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ ẹbọ ìrántí lẹ́yìn ó ti obìnrin náà mu omi. 27 ó ti obìnrin yìí mu omi náà, ó jẹ́ obìnrin náà ti ba ara rẹ̀ jẹ́, ó ṣe àìṣòótọ́ ọkọ rẹ̀, omi ń ègún , yóò wọ ara rẹ̀, yóò fa ìrora kíkorò fún un, ikùn rẹ̀ yóò , itan rẹ̀ yóò jẹrà dànù, yóò di ẹni ègún láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 28 Ṣùgbọ́n jẹ́ obìnrin náà ba ara rẹ̀ jẹ́, jẹ́ mímọ́, yóò bọ́ nínú ̀bi, yóò le bímọ.

29 " Èyí ni òfin owú jíjẹ nígbà obìnrin lábẹ́ ọkọ ṣe a ṣe ṣe, ó ba ara rẹ̀ jẹ́, 30 tàbí nígbà ̀owú jíjẹ ọkùnrin kan nítorí ó funra ìyàwó rẹ̀. Àlùfáà yóò obìnrin náà dúró níwájú Olúwa yóò ṣe gẹ́gẹ́ òfin ti fún un. 31 Ara ọkọ rẹ̀ mọ́ nínú ̀ṣẹ̀ yìí ṣùgbọ́n obìnrin náà yóò ru ̀bi ̀ṣẹ̀ rẹ̀.’ "

Veja também