Pular para o conteúdo
Publicidade

Números 11

Kíkùn àwọn ènìyàn àti iná láti ̀dọ̀ Olúwa

1 Àwọn ènìyàn ń ṣe àròyé nípa wàhálà wọn etí ìgbọ́ Olúwa. Ìbínú Olúwa ru sókè nígbà ó gbọ́ àròyé yìí. Nígbà náà ni iná jáde láti ̀dọ̀ Olúwa bọ́ àárín wọn, ó run àwọn òpin ibùdó. 2 Nígbà náà ni àwọn ènìyàn kígbe Mose, Mose gbàdúrà Olúwa iná náà . 3 Wọ́n ń pe ibẹ̀ Tabera nítorí , iná láti ̀dọ̀ Olúwa láàrín wọn.

Ẹran àparò láti ̀dọ̀ Olúwa

4 11.4: 1Kọ 10.6. Àwọn ̀pọ̀ ènìyàn aláìníláárí láàrín àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀ọkàn ìfẹ́kúfẹ̀́ wọn fi ìtara béèrè fún oúnjẹ mìíràn, àwọn ọmọ Israẹli náà bẹ̀rẹ̀ í sọkún , "i á ẹran jẹ báyìí! 5 Àwa rántí ẹja à ń jẹ lọ́fẹ̀́ Ejibiti, apálà, bàrà, ewébẹ̀, àlùbọ́àti àwọn ̀fọ́ mìíràn. 6 Ṣùgbọ́n báyìí gbogbo ara wa ti gbẹ, ohun mìíràn láti jẹ àfi manna nìkan a yìí!"

7 Manna náà dàbí èso korianderi, ìrísí rẹ̀ dàbí oje igi. 8 Àwọn ènìyàn náà ń lọ káàkiri láti o, wọn ó lọ̀ ́ lórí ọlọ tàbí wọ́n gún un nínú odó. Wọ́n le é nínú ìkòkò tàbí wọn ó fi ṣe àkàrà, adùn rẹ̀ yóò dàbí adùn ohun a fi òróró ṣe. 9 Nígbà ìrì ̀ ibùdó lórí ni manna náà máa ń bọ́ pẹ̀rẹ̀.

10 Mose gbọ́ àwọn ènìyàn ń sọkún gbogbo ìdílé wọn, oníkálùkù ẹnu-ọ̀àgọ́ tirẹ̀. Olúwa bínú gidigidi. Inú Mose bàjẹ́ pẹ̀. 11 Mose béèrè lọ́wọ́ Olúwa , "o fi wàhálà yìí ìránṣẹ́ rẹ? ni mo ṣe n fi tẹ lọ́rùn ìwọ fi di ẹrù àwọn ènìyàn wọ̀nyí mi lórí. 12 Èmi ni mo ha lóyún gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí ? Àbí èmi wọn? ìwọ fi sọ fún mi , máa gbé wọn oókan àyà rẹ, gẹ́gẹ́ abiyamọ ti máa ń gbe ọmọ ọmú lọ ilẹ̀ o ti búra láti fún àwọn baba ńlá wọn. 13 Níbo ni n ó ti ẹran fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí? Nítorí wọ́n ń sọkún mi , Fún wa lẹ́ran jẹ́!’ 14 Èmi nìkan dágbé wàhálà àwọn ènìyàn wọ̀nyí, ẹrù wọn ti wúwo fún mi. 15 ó ṣe báyìí ni ìwọ ó ṣe máa ṣe fún mi, kúkú pa báyìí, mo ti ojúrere rẹ pàdéojú mi ba à ìparun mi."

16 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "àádọ́rin ọkùnrin nínú àwọn àgbàgbà àwọn ọmọ Israẹli, àwọn o mọ̀ gẹ́gẹ́ olórí àti olóyè láàrín àwọn ènìyàn sínú àgọ́ ìpàdé, wọ́n dúró níwájú mi. 17 Èmi ó sọ̀kalẹ̀ yín sọ̀rọ̀ níbẹ̀. Èmi ó díẹ̀ nínú agbára ̀ń bẹ lára rẹ láti fi orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Wọn ó máa ràn ́ lọ́wọ́ láti ru àjàgà àwọn ènìyàn ó ṣe ìwọ nìkan ni ó o máa ru àjàgà náà.

18 "Sọ fún àwọn ènìyàn náà , ya ara yín mímọ́ ìmúrasílẹ̀ fún ̀la, ó jẹ ẹran. Nítorí Olúwa ti gbọ́ igbe ẹkún yín, èyí sun , "Ìbá ṣe a ẹran jẹ ni! Ó sàn fún wa Ejibiti báyìí lọ!" Nítorí náà ni Olúwa yóò fi fún yín ẹran, ó jẹ ́. 19 i jẹ ́ fún ọjọ́ kan, ọjọ́ méjì, ọjọ́ márùn-ún, ọjọ́ mẹ́wàá tàbí ogúnjọ́ lásán, 20 ṣùgbọ́n fún odidi oṣù kan, títí ẹran náà yóò fi máa yọ imú yín, yóò yín, nítorí ti kẹ́gàn Olúwa ó láàrín yín, ti sọkún fún un , "a fi kúrò Ejibiti gan an?" ’ "

21 Ṣùgbọ́n Mose sọ , "Mo láàrín ọgbọ̀n ̀kẹ́ ènìyàn (600,000) ni ìrìnkiri, ó sọ , Èmi ó fún wọn ẹran láti jẹ fún oṣù kan gbáko!22 Ǹjẹ́ a tilẹ̀ pa àgbò ẹran àti ọmọ ẹran, yóò ha wọn ? Tàbí a tilẹ̀ pa gbogbo ẹja inú omi fún wọn, yóò wa ?"

23 Olúwa Mose lóhùn , "Ọwọ́ Olúwa ha kúrú ? Ìwọ yóò ri nísinsin yìí bóyá ̀rọ̀ mo sọ yóò ṣẹ tàbí ni í ṣẹ."

24 Mose jáde, ó sọ ohun Olúwa fún àwọn ènìyàn. Ó àwọn àádọ́rin àgbàgbà Israẹli dúró àgọ́ . 25 Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú àwọ̀ sánmọ̀ ó wọn sọ̀rọ̀, ó lára ̀lára Mose ara àwọn àádọ́rin àgbàgbà náà, Ó ṣẹlẹ̀ nígbà ̀náà wọn, wọ́n sọtẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí wọn sọtẹ́lẹ̀ mọ́.

26 Àwọn ọkùnrin méjì, orúkọ wọn ń jẹ́ Eldadi àti Medadi kúrò nínú àgọ́. Orúkọ wọn lára àádọ́rin àgbàgbà yìí ṣùgbọ́n wọn jáde nínú àgọ́ síbẹ̀ ̀náà wọn, wọ́n sọtẹ́lẹ̀ nínú àgọ́. 27 Ọmọkùnrin kan sáré lọ sọ fún Mose , "Eldadi àti Medadi ń sọtẹ́lẹ̀ nínú àgọ́."

28 Joṣua ọmọ Nuni í ṣe ìránṣẹ́ Mose, láti kékeré jẹ́ ̀kan nínú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ dáhùn , "Mose olúwa mi, wọn lẹ́kun!"

29 Mose fún un , "Àbí ìwọ ń jowú nítorí mi? Ìbá ti , gbogbo àwọn ènìyàn Olúwa jẹ́ wòlíì, Olúwa fi ̀rẹ̀ wọn lára!" 30 Mose àti àwọn àgbàgbà Israẹli yìí padà sínú àgọ́.

31 Afẹ́fẹ́ jáde láti ̀dọ̀ Olúwa ó àparò láti inú Òkun. Ó wọ́n káàkiri gbogbo ibùdó ìwọ̀n gíga ẹsẹ̀ bàtà mẹ́ta sórí ilẹ̀, ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ kan gbogbo àyíká. 32 gbogbo ọjọ́ náà àti òru, títí ọjọ́ kejì ni àwọn ènìyàn fi ń àparò yìí, ẹni kéré jùlọ ìwọ̀n homeri mẹ́wàá, wọ́n ṣà wọ́n sílẹ̀ fún ara wọn gbogbo ibùdó. 33 Ṣùgbọ́n nígbà ẹran náà láàrín eyín wọn, di wọ́n jẹ ́, ìbínú Olúwa ru àwọn ènìyàn, ó pa wọ́n pẹ̀àjàkálẹ̀-ààrùn. 34 11.34: 1Kọ 10.6.Torí èyí ni wọ́n ṣe pe ibẹ̀ Kibirotu-Hattaafa nítorí níbẹ̀ ni wọ́n gbé sìnkú àwọn ènìyàn ̀kánjúwà oúnjẹ .

35 Àwọn ènìyàn yòókù gbéra láti Kibirotu-Hattaafa lọ pa ibùdó Haserotu wọ́n dúró níbẹ̀.

Veja também