Publicidade

Números 23

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ àkọ́kọ́ Balaamu

1 Balaamu fún Balaki , "Kọ́ pẹpẹ méje fún mi níbí, o akọ màlúù méje àti àgbò méje fún mi." 2 Balaki ṣe Balaamu ti sọ, àwọn méjèèjì fi akọ màlúù kọ̀̀kan àti àgbò kọ̀̀kan ẹbọ lórí pẹpẹ kọ̀̀kan.

3 Nígbà náà Balaamu sọ fún Balaki , "Dúró ti ẹbọ sísun rẹ èmi lọ ̀gbẹ́ kan. Bóyá Olúwa yóò farahàn . Ohunkóhun ó fihàn , èmi yóò fún ." Nígbà náà ó lọ ibi gíga.

4 Ọlọ́run pàdé rẹ̀, Balaamu sọ , "Mo ṣe pẹpẹ méje, lórí pẹpẹ kọ̀̀kan mo ti fi akọ màlúù àti àgbò kọ̀̀kan ẹbọ."

5 Olúwa fi ̀rọ̀ ẹnu Balaamu ó , "Padà ̀dọ̀ Balaki o jẹ́ iṣẹ́ yìí fún un."

6 Ó padà ̀dọ̀ rẹ̀ ó ba ó dúró ti ẹbọ sísun rẹ̀, pẹ̀gbogbo àwọn ìjòyè Moabu. 7 Nígbà náà ni Balaamu sọ ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ jáde ,

"Balaki mi láti Aramu ,

ọba Moabu láti òkè ìlà-oòrùn

Ó , fi Jakọbu fún mi;

, o jẹ́rìí Israẹli.

8 Báwo èmi ó ṣe fi

àwọn Ọlọ́run fi ?

Báwo ni èmi ó ṣe wọn

àwọn Olúwa ?

9 Láti ṣóńṣó ibi gíga orí àpáta ni mo ti wọn,

láti orí ibi gíga ni mo ti ń wọ́n.

Mo àwọn ènìyàn ń gbé lọ́tọ̀

wọn ka ará wọn kún ara àwọn orílẹ̀-èdè.

10 Ta ni ó ka eruku Jakọbu

tàbí ka ìdámẹ́rin Israẹli?

Jẹ́ èmi ikú olódodo,

ìgbẹ̀yìn mi ó tirẹ̀!"

11 Balaki sọ fún Balaamu , "lo ṣe fún mi? Mo gbé láti fi àwọn ̀mi , ṣùgbọ́n o ṣe nǹkan kan, ṣùgbọ́n o bùkún wọn!"

12 Ó dáhùn , "Ṣé n sọ nǹkan Olúwa fi mi lẹ́nu?"

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ èkejì Balaamu

13 Nígbà náà Balaki sọ fún un , "pẹ̀mi ibòmíràn o ti wọn; á díẹ̀, ṣùgbọ́n í ṣe gbogbo wọn. Láti ibẹ̀, fi wọ́n fún mi." 14 Ó lọ pápá Sofimu orí òkè Pisga, ó kọ́ pẹpẹ méje síbẹ̀ ó fi akọ màlúù àti àgbò kọ̀̀kan ẹbọ lórí pẹpẹ kọ̀̀kan.

15 Balaamu ṣo fún Balaki , "Dúró níbí ti ẹbọ sísun rẹ nígbà mo lọ pàdé rẹ̀ níbẹ̀."

16 Olúwa pàdé Balaamu ó fi ̀rọ̀ ẹnu , "Padà lọ ̀dọ̀ Balaki o jíṣẹ́ fún un."

17 Nígbà náà ó lọ ̀dọ̀ rẹ̀ ó à ó dúró ti ẹbọ sísun rẹ̀ pẹ̀àwọn ìjòyè Moabu. Balaki béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "ni Olúwa ?"

18 Nígbà náà ó bẹ̀rẹ̀ ̀rọ̀ sísọ,

"Dìde, Balaki;

o gbọ́ mi ọmọ Sippori.

19 Ọlọ́run í ṣe ènìyàn, yóò fi purọ́,

tàbí ọmọ ènìyàn, ó ọkàn rẹ̀ padà.

Ǹjẹ́ ó sọ̀rọ̀ ó ṣe é?

Ǹjẹ́ ó ti ṣèlérí ó mu un ṣẹ?

20 Èmi gba àṣẹ láti bùkún;

Ó ti bùkún, èmi yípadà.

21 "̀ṣẹ̀ kankan nínú Jakọbu,

búburú kankan nínú Israẹli.

Olúwa Ọlọ́run wọn pẹ̀wọn.

Ìhó ọba pẹ̀wọn.

22 Ọlọ́run wọn jáde láti Ejibiti ,

wọ́n agbára màlúù ẹhànnà.

23 àfọ̀ṣẹ Jakọbu,

tàbí àfọ̀ṣẹ àwọn Israẹli.

Nísinsin yìí a ó sọ nípa ti Jakọbu

àti Israẹli, Wo ohun Ọlọ́run ti ṣe!

24 Àwọn ènìyàn náà yóò dìde abo kìnnìún;

wọ́n yóò gbé ara wọn sókè i kìnnìún

òun yóò dùbúlẹ̀ títí yóò fi jẹ ohun ọdẹ

títí yóò fi mu nínú ̀jẹ̀ ohun pípa."

25 Nígbà náà ni Balaki fún Balaamu , "O kúkú fi wọ́n , bẹ́̀ ni o súre fún wọn rárá!"

26 Balaamu dáhùn ó fún Balaki , "Ǹjẹ́ èmi ha ti fún , gbogbo èyí Olúwa sọ, òun ni èmi yóò ṣe?"

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ ̀kẹta Balaamu

27 Nígbà náà Balaki sọ fún Balaamu , "jẹ́ èmi ó lọ ibòmíràn bóyá yóò tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn ó fi wọ́n láti ibẹ̀ lọ." 28 Balaki gbé Balaamu orí òkè Peori, ó kọjú aginjù.

29 Balaamu fún Balaki , "Mọ pẹpẹ méje fún mi níbí o pèsè akọ màlúù àti àgbò fún mi." 30 Balaki ṣe Balaamu ti sọ fún un, ó gbé akọ màlúù kan àti àgbò lórí pẹpẹ kọ̀̀kan.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-