Publicidade

Números 25

Moabu tan Israẹli jẹ

1 Nígbà àwọn Israẹli dúró Ṣittimu, àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ í ṣe àgbèrè pẹ̀àwọn ọmọbìnrin Moabu, 2 ó wọ́n ibi ẹbọ òrìṣà wọn. Àwọn ènìyàn náà jẹun wọ́n foríbalẹ̀ níwájú òrìṣà wọn. 3 Báyìí ni Israẹli ṣe darapọ̀ mọ́ wọn wọ́n jọ ń sin Baali-Peori. Ìbínú Olúwa ru wọn.

4 Olúwa sọ fún Mose , "gbogbo àwọn olórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, pa wọ́n o fi wọ́n kọ́ sórí igi gbangba nínú oòrùn níwájú Olúwa, ìbínú Olúwa kúrò ̀dọ̀ Israẹli."

5 Mose sọ fún àwọn onídàájọ́ Israẹli, "Ẹnìkọ̀̀kan yín gbọdọ̀ pa arákùnrin rẹ̀ èyí ó darapọ̀ fífi orí balẹ̀ fún Baali-Peori."

6 Nítòótọ́ ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin Israẹli obìnrin Midiani síwájú ojú Mose àti gbogbo ìjọ ti Israẹli wọ́n ń sọkún àbáwọlé àgọ́ ìpàdé. 7 Nígbà Finehasi, ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni, àlùfáà, èyí, ó fi ìjọ sílẹ̀, pẹ̀̀kọ̀ ọwọ́ rẹ̀. 8 Ó tẹ̀arákùnrin Israẹli yìí lọ sínú àgọ́. Ó fi ̀kọ̀ gún àwọn méjèèjì àgúnyọ láti ara ọkùnrin Israẹli àti ara obìnrin náà. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn lórí àwọn ọmọ Israẹli dúró; 9 ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ó nínú àjàkálẹ̀-ààrùn náà jẹ́ ẹgbàá méjìlá (24,000).

10 Olúwa tún sọ fún Mose , 11 "Finehasi ọmọ Eleasari ọmọ Aaroni, àlùfáà, ti ìbínú mi padà kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli, nítorí ó ìtara èmi náà ti ìtara fún iyì mi láàrín wọn, ó jẹ́ èmi pa wọ́n run nínú ìtara mi wọn. 12 Nítorí náà sọ fún un èmi ṣe májẹ̀àlàáfíà mi pẹ̀rẹ̀. 13 Òun àti irú-ọmọ rẹ̀ yóò májẹ̀láéláé fún iṣẹ́ àlùfáà, nítorí ó ìtara fún Ọlọ́run rẹ̀ láti fi yẹ́ Ọlọ́run , ó ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli."

14 Orúkọ ọmọ Israẹli a pa pẹ̀obìnrin Midiani náà ni Simri, ọmọ Salu, olórí ilé kan nínú àwọn ọmọ Simeoni. 15 Orúkọ ọmọbìnrin Midiani náà a pa Kosbi ọmọbìnrin Suri, ṣe olóyè àwọn ̀kan nínú ìdílé kan Midiani.

16 Olúwa tún sọ fún Mose , 17 "Ka àwọn ará Midiani ̀, o pa wọ́n, 18 nítorí wọ́n ṣe yín gẹ́gẹ́ ̀nígbà wọ́n tàn yín nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Peori, àti arábìnrin wọn Kosbi ọmọbìnrin ìjòyè Midiani kan, obìnrin a pa nígbà àjàkálẹ̀-ààrùn ṣẹlẹ̀ nítorí Peori."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-