Publicidade

Números 12

Miriamu Àti Aaroni tako Mose

1 Miriamu àti Aaroni sọ̀rọ̀-òdì Mose nítorí ó fẹ́ obìnrin ará Etiopia. 2 Wọ́n , "Nípa Mose nìkan ni Olúwa ti sọ̀rọ̀ , ha ti ipa wa sọ̀rọ̀ ?" Olúwa gbọ́ èyí.

3 (Mose jẹ́ ọlọ́kàn tútù ju gbogbo ènìyàn lórí ilẹ̀ ayé lọ).

4 Lẹ́̀kan náà ni Olúwa sọ fún Mose, Aaroni àti Miriamu , "̀yin mẹ́tẹ̀̀ta, jáde sínú àgọ́ ìpàdé." Àwọn mẹ́tẹ̀̀ta jáde síta. 5 Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú ̀wọ́n ìkùùkuu, ó dúró ẹnu-ọ̀àgọ́, ó Aaroni àti Miriamu. Àwọn méjèèjì bọ́ síwájú, 6 Ó , "gbọ́ ̀rọ̀ mi,

"wòlíì Olúwa láàrín yín,

Èmi Olúwa a máa fi ara à mi hàn án ojúran,

Èmi a máa a sọ̀rọ̀ nínú àlá.

7 12.7: Hb 3.2,5,6. Ṣùgbọ́n èyí bẹ́̀ pẹ̀Mose ìránṣẹ́ mi;

ó jẹ́ olóòtítọ́ nínú gbogbo ilé mi.

8 12.8: El 33.11; De 34.10. Mo ń a sọ̀rọ̀ ojúkojú,

̀rọ̀ yékéyéké í ṣe òwe,

ó àwòrán Olúwa.

̀yin ṣe bẹ̀

láti sọ̀rọ̀-òdì Mose ìránṣẹ́ mi?"

9 Ìbínú Olúwa ru sókè wọn Olúwa fi wọ́n sílẹ̀.

10 Nígbà ìkùùkuu kúrò lórí àgọ́ lójijì ni Miriamu di adẹ́tẹ̀, ó funfun i yìnyín. Aaroni padà wo Miriamu ó i ó ti di adẹ́tẹ̀, 11 Aaroni fún Mose , "Jọ̀wọ́ olúwa mi, ṣe ka ̀ṣẹ̀, èyí a fi ìwà òmùgọ̀ wa lọ́rùn. 12 ṣe jẹ́ ó dàbí òkú ọmọ a , ìdajì ara rẹ̀ ti dànù."

13 Torí èyí Mose kígbe Olúwa, "Ọlọ́run, jọ̀wọ́, un láradá!"

14 12.14: Nu 5.2,3. Olúwa Mose lóhùn, "baba rẹ̀ tutọ́ i lójú, ojú wa í í fún ọjọ́ méje? a dúró ̀yìn ibùdó fún ọjọ́ méje, lẹ́yìn èyí ki a ó le wọlé." 15 Miriamu dúró ̀yìn ibùdó fún ọjọ́ méje, àwọn ènìyàn tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn títí Miriamu fi wọ inú ibùdó padà.

16 Lẹ́yìn èyí, àwọn ènìyàn kúrò Haserotu, wọ́n pa ibùdó aginjù Parani.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-